< Zechariah 5 >

1 Nígbà náà ni mo yípadà, mo sì gbé ojú mi sókè, mo sì wò, sì kíyèsi i, ìwé kíká ti ń fò.
Anante kesga hu'na kogeno mago regazari'naza avontafemo'a monafi hareno enevige'na kogeno,
2 Ó sì wí fún mi pé, “Kí ni ìwọ rí?” Èmi sì dáhùn pé, “Mo rí ìwé kíká tí ń fò; gígùn rẹ̀ jẹ́ ogún ìgbọ̀nwọ́, ìbú rẹ̀ sì jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́wàá.”
ana ankeromo'a anage huno nantahigene, Na'a negane? Hige'na nagra amanage hu'na hu'noe, regazarinte avontafe'mofona zaza'amo'a 10 mita higeno, atupa'amo'a 5 mita hu'nea avontafemo hareno vano nehige'na negoe.
3 Ó sì wí fún mi pé, “Èyí ni ègún tí ó jáde lọ sí gbogbo ilẹ̀ ayé, nítorí gbogbo àwọn tí ó bá jalè ni a ó ké kúrò láti ìhín lọ nípa rẹ̀; gbogbo àwọn tí ó bá sì búra èké ni a ó ké kúrò láti ìhín lọ nípa rẹ̀.
Hugeno anante agra amanage huno nasami'ne, Ama'i maka mopafima mani'naza vahe'ma zamazeri havizama hania kazusi zane. Na'ankure kumzufama nesaza vahera mago kaziga avontafepi kemo'ma hu'nea kante anteno, ama mopafintira maka zamazeri atre vaganereno, havigema hu'za huvempama nehaza vahera mago kaziga avontafepi kemo'ma hu'nea kante anteno, ama mopafintira zamazeri atregahie.
4 Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, ‘Èmi yóò mú un jáde, Èmi yóò si wọ inú ilé olè lọ, àti inú ilé ẹni ti o bá fi orúkọ mi búra èké, yóò si wà ni àárín ilé rẹ̀, yóò si rún pẹ̀lú igi àti òkúta inú rẹ̀.’”
Monafi sondia vahe'mofo Ra Anumzamo'a huno, Nagra ana kazusizana huntesugeno kumazufama nesaza vahe nompine, nagri nagifima havigema hu'za huvempama nehaza vahe'mokizmi nompinena ufreno, ana nontamimpi mani'neno, maka noma ki'naza zafane havenena neno eri vagaregahie.
5 Angẹli tí ń bá mi sọ̀rọ̀ sì jáde lọ, ó sì wí fún mi pé, “Gbé ojú rẹ sókè nísinsin yìí, kí o sì wo nǹkan tí yóò jáde lọ.”
Ana zama ketogeno'a nagri'enema nanekema nehia ankeromo'a eazamo amanage huno eme nasami'ne, Na'a ne-efi kesga hunka ko.
6 Mo sì wí pé, “Kí ni nǹkan náà?” Ó sì wí pé, “Èyí ni òsùwọ̀n tí ó jáde lọ.” Ó sì wí pé, “Èyí ni àwòrán ní gbogbo ilẹ̀ ayé.”
Anage hige'na nagra hu'na, e'i zana na'ane? Hu'na antahigogeno amanage huno nasami'ne, ama zana witima erinte'za kna'ama refkoma nehaza ekaeka kukino, (ephah) ama zana mika ama mopafima nemaniza vahe'mokizmi kefo avu'avazane.
7 Sì kíyèsi i, a gbé tálẹ́ǹtì òjé sókè, obìnrin kan sì nìyìí tí ó jókòó sí àárín àpẹẹrẹ òsùwọ̀n.
Ana ekaeka ku'mofona knanentake avaza'a eri anagisga higena koana, ana kupina mago a' mani'negena negogeno,
8 Ó sì wí pé, “Èyí ni ìwà búburú.” Ó sì ti sí àárín òsùwọ̀n, ó sì ju ìdérí òjé sí ẹnu rẹ̀.
ana ankeromo'a amanage hu'ne, Ama a'mo'a kefo avu'avazamofo hu avame huno mani'ne, nehuno ana ara retufegeno ana ekaeka kupi uramigeno knanentake'ma hu'nea avaza'a erigi'ne.
9 Mo sì gbé ojú mi sókè, mo sì wò, sì kíyèsi i, obìnrin méjì jáde wá, ẹ̀fúùfù sì wá nínú ìyẹ́ wọn; nítorí wọ́n ní ìyẹ́ bí ìyẹ́ àkọ̀, wọ́n sì gbé àpẹẹrẹ òsùwọ̀n náà dé àárín méjì ayé àti ọ̀run.
Anante kesga hu'na koana, tare a'tremokea zahopi hareke e'na'e. Ana a'tremokizni zanagekonamo'a tusizankna afi patomofo agekona'agna hu'neankike, ekaeka kupima mani'nea ara, ana ekaeka ku'aga eme azerisga huke vu'na'e.
10 Mo sì sọ fún angẹli tí ó ń bá mi sọ̀rọ̀ pé, “Níbo ni àwọn wọ̀nyí ń gbé òsùwọ̀n náà lọ.”
Anante nagri'enema nanekema nehia ankerona antahige'na, iga e'i ekaeka kura erike neva'e?
11 Ó si wí fún mi pé, “Sí orílẹ̀-èdè Babeli láti kọ ilé fún un. Tí ó bá ṣetán, a ó sì fi ìdí rẹ̀ mulẹ̀, a o sì fi ka orí ìpìlẹ̀ rẹ̀ níbẹ̀.”
Anagema hu'na antahigogeno'a amanage huno nasami'ne, Sinari moparega mono noma'a ome ki'za ante'naku avre'za nevazankino, noma'ama ome ki vagama retenu'za, ana ekaeka kura trate ome antegahaze.

< Zechariah 5 >