< Zechariah 5 >

1 Nígbà náà ni mo yípadà, mo sì gbé ojú mi sókè, mo sì wò, sì kíyèsi i, ìwé kíká ti ń fò.
Ningĩ ngĩcooka ngĩtiira maitho, na rĩrĩ, hau mbere yakwa ngĩona ibuku-rĩa-gĩkũnjo rĩombũkaga rĩera-inĩ.
2 Ó sì wí fún mi pé, “Kí ni ìwọ rí?” Èmi sì dáhùn pé, “Mo rí ìwé kíká tí ń fò; gígùn rẹ̀ jẹ́ ogún ìgbọ̀nwọ́, ìbú rẹ̀ sì jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́wàá.”
Nake akĩnjũũria atĩrĩ, “Nĩ kĩĩ ũroona?” Na niĩ ngĩmũcookeria atĩrĩ, “Ndĩrona ibuku-rĩa-gĩkũnjo rĩrombũka rĩera-inĩ, rĩrĩ na ũraihu wa mĩkono mĩrongo ĩĩrĩ na wariĩ wa mĩkono ikũmi.”
3 Ó sì wí fún mi pé, “Èyí ni ègún tí ó jáde lọ sí gbogbo ilẹ̀ ayé, nítorí gbogbo àwọn tí ó bá jalè ni a ó ké kúrò láti ìhín lọ nípa rẹ̀; gbogbo àwọn tí ó bá sì búra èké ni a ó ké kúrò láti ìhín lọ nípa rẹ̀.
Nake akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Gĩkĩ nĩ kĩrumi kĩrĩa gĩgũtambũrũka bũrũri wothe; nĩgũkorwo kũringana na ũrĩa mwena ũmwe warĩo wandĩkĩtwo, mũici o wothe no nginya agaathaamio, naguo mwena ũcio ũngĩ warĩo ũkandĩkwo atĩrĩ, ũrĩa wothe wĩhĩtaga na maheeni nĩagathaamio.
4 Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, ‘Èmi yóò mú un jáde, Èmi yóò si wọ inú ilé olè lọ, àti inú ilé ẹni ti o bá fi orúkọ mi búra èké, yóò si wà ni àárín ilé rẹ̀, yóò si rún pẹ̀lú igi àti òkúta inú rẹ̀.’”
Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga atĩrĩ, ‘Nĩngatũma kĩrumi kĩu, nakĩo nĩgĩgatoonya nyũmba ya mũici na nyũmba ya ũrĩa wĩhĩtaga na maheeni akĩgwetaga rĩĩtwa rĩakwa. Gĩgaikara nyũmba yake na kĩmĩanange yothe, kĩanange mbaũ ciayo na mahiga mayo.’”
5 Angẹli tí ń bá mi sọ̀rọ̀ sì jáde lọ, ó sì wí fún mi pé, “Gbé ojú rẹ sókè nísinsin yìí, kí o sì wo nǹkan tí yóò jáde lọ.”
Ningĩ mũraika ũrĩa wanjaragĩria akiumĩra akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Tiira maitho wone nĩ kĩĩ gĩkĩ kĩroimĩra.”
6 Mo sì wí pé, “Kí ni nǹkan náà?” Ó sì wí pé, “Èyí ni òsùwọ̀n tí ó jáde lọ.” Ó sì wí pé, “Èyí ni àwòrán ní gbogbo ilẹ̀ ayé.”
Ngĩmũũria atĩrĩ, “Nĩ kĩĩ gĩkĩ?” Nake akĩnjookeria atĩrĩ, “Nĩ gĩkabũ gĩa gũthima.” Agĩcooka akiuga atĩrĩ, “Ũyũ nĩguo waganu wa andũ, ũrĩa ũrĩ bũrũri wothe.”
7 Sì kíyèsi i, a gbé tálẹ́ǹtì òjé sókè, obìnrin kan sì nìyìí tí ó jókòó sí àárín àpẹẹrẹ òsùwọ̀n.
Nakĩo gĩkunĩko gĩa kĩgera gĩgĩkunũrwo, na rĩrĩ, hau thĩinĩ wa gĩkabũ ngĩona mũndũ-wa-nja waikarĩte thĩ ho.
8 Ó sì wí pé, “Èyí ni ìwà búburú.” Ó sì ti sí àárín òsùwọ̀n, ó sì ju ìdérí òjé sí ẹnu rẹ̀.
Nake akiuga atĩrĩ, “Ũyũ nĩwe Nyawaganu,” nake akĩmũcookia thĩinĩ wa gĩkabũ na agĩgĩkunĩka na gĩkunĩko kĩu gĩa kĩgera.
9 Mo sì gbé ojú mi sókè, mo sì wò, sì kíyèsi i, obìnrin méjì jáde wá, ẹ̀fúùfù sì wá nínú ìyẹ́ wọn; nítorí wọ́n ní ìyẹ́ bí ìyẹ́ àkọ̀, wọ́n sì gbé àpẹẹrẹ òsùwọ̀n náà dé àárín méjì ayé àti ọ̀run.
Ngĩcooka ngĩtiira maitho, na rĩrĩ, hau mbere yakwa ngĩona andũ-a-nja eerĩ, mareretio nĩ rũhuho; tondũ maarĩ na mathagu ta ma njũũ, makĩoya gĩkabũ kĩu magĩgĩtwara rĩera-inĩ.
10 Mo sì sọ fún angẹli tí ó ń bá mi sọ̀rọ̀ pé, “Níbo ni àwọn wọ̀nyí ń gbé òsùwọ̀n náà lọ.”
Ngĩũria mũraika ũcio wanjaragĩria atĩrĩ, “Maratwara gĩkabũ kĩu kũ?”
11 Ó si wí fún mi pé, “Sí orílẹ̀-èdè Babeli láti kọ ilé fún un. Tí ó bá ṣetán, a ó sì fi ìdí rẹ̀ mulẹ̀, a o sì fi ka orí ìpìlẹ̀ rẹ̀ níbẹ̀.”
Nake akĩnjookeria atĩrĩ, “Maragĩtwara bũrũri wa Babuloni magagĩakĩre nyũmba kuo. Yarĩka-rĩ, gĩkabũ kĩu makĩige kuo handũ hakĩo.”

< Zechariah 5 >