< Zechariah 2 >

1 Mó si tún gbé ojú mi, sókè, mo sì wò, sì kíyèsi i, ọkùnrin kan ti o mú okùn ìwọ̀n lọ́wọ́ rẹ̀.
Andin mǝn beximni kɵtürüp, mana ⱪolida ɵlqǝm tanisini tutⱪan bir adǝmni kɵrdüm
2 Mo sí wí pé, “Níbo ni ìwọ ń lọ?” O sí wí fún mí pé, “Láti wọn Jerusalẹmu, láti rí iye ìbú rẹ̀, àti iye gígùn rẹ̀.”
wǝ uningdin: «Nǝgǝ barisǝn?» dǝp soridim. U manga: «Mǝn Yerusalemni ɵlqigili, uning kǝngliki wǝ uzunluⱪini [ɵlqǝp] bilgili barimǝn» — dedi.
3 Sì kíyèsi i, angẹli tí ó ń bá mi sọ̀rọ̀ jáde lọ, angẹli mìíràn si jáde lọ pàdé rẹ̀.
Mana, mǝn bilǝn sɵzlixiwatⱪan pǝrixtǝ qiⱪti; yǝnǝ bir pǝrixtǝ uning bilǝn kɵrüxüxkǝ qiⱪti
4 Ó si wí fún un pé, “Sáré, sọ fún ọ̀dọ́mọkùnrin yìí wí pé, ‘A ó gbé inú Jerusalẹmu bi ìlú ti kò ní odi, nítorí ọ̀pọ̀ ènìyàn àti ohun ọ̀sìn inú rẹ̀.
wǝ uningƣa mundaⱪ dedi: — Yügür, bu yax yigitkǝ sɵz ⱪil, uningƣa mundaⱪ degin: — «Yerusalem ɵzidǝ turuwatⱪan adǝmlǝrning wǝ mallarning kɵplükidin sepilsiz xǝⱨǝrlǝrdǝk bolidu.
5 Olúwa wí pé: Èmi ó sì jẹ́ odi iná fún un yíká, èmi ó sì jẹ́ ògo láàrín rẹ̀.’
— wǝ Mǝn Pǝrwǝrdigar uning ǝtrapiƣa ot-yalⱪun sepili, uning iqidiki xan-xǝripi bolimǝn.
6 “Wá! Wá! Sá kúrò ni ilẹ̀ àríwá,” ni Olúwa wí, “nítorí pé bí afẹ́fẹ́ mẹ́rin ọ̀run ni mo tú yín káàkiri,” ni Olúwa wí.
— Ⱨoy! Ⱨoy! Ximaliy zemindin ⱪeqinglar, — dǝydu Pǝrwǝrdigar, — qünki Mǝn silǝrni asmandiki tɵt tǝrǝptin qiⱪⱪan xamaldǝk tarⱪitiwǝtkǝn, dǝydu Pǝrwǝrdigar».
7 “Gbà ara rẹ̀ sílẹ̀, ìwọ Sioni, ìwọ tí ó ń bà ọmọbìnrin Babeli gbé.”
«— Ⱨǝy! I Babil ⱪizi bilǝn turƣuqi Zion, ⱪaqⱪin!
8 Nítorí báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Lẹ́yìn ògo rẹ̀ ni a ti rán mi sí àwọn orílẹ̀-èdè tí ń kó yin: nítorí ẹni tí ó tọ́ yin, ó tọ́ ọmọ ojú rẹ̀.
Qünki samawi ⱪoxunlarning Sǝrdari bolƣan Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — Ɵz xan-xǝripini dǝp U Meni silǝrni bulang-talang ⱪilƣan ǝllǝrgǝ ǝwǝtti; qünki kim silǝrgǝ qeⱪilsa, xu Ɵzining kɵz ⱪariqoⱪiƣa qeⱪilƣan bolidu.
9 Nítorí kíyèsi i, èmi ó gbọn ọwọ́ mi sí orí wọn, wọn yóò sì jẹ́ ìkógun fún ìránṣẹ́ wọn: ẹ̀yin yóò sì mọ̀ pé, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni ó rán mi.
Qünki mana, Mǝn Ɵz ⱪolumni ularning üstigǝ silkiymǝn, ular ɵzlirigǝ ⱪul ⱪilinƣuqilarƣa olja bolidu; xuning bilǝn silǝr samawi ⱪoxunlarning Sǝrdari bolƣan Pǝrwǝrdigarning Meni ǝwǝtkǝnlikini bilisilǝr.
10 “Kọrin kí o sì yọ̀, ìwọ ọmọbìnrin Sioni. Nítorí èmi ń bọ̀ àti pé èmi yóò sì gbé àárín rẹ,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Nahxilarni yangritip xadlan, i Zion ⱪizi; qünki mana, keliwatimǝn, arangda makanliximǝn, dǝydu Pǝrwǝrdigar,
11 “Ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè ni yóò dàpọ̀ mọ́ Olúwa ní ọjọ́ náà, wọn yóò sì di ènìyàn mi, èmi yóò sì gbé àárín rẹ, ìwọ yóò sì mọ̀ pé, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni ó rán mi sí ọ.
— wǝ xu künidǝ kɵp ǝllǝr Pǝrwǝrdigarƣa baƣlinidu, Manga bir hǝlⱪ bolidu; arangda makanliximǝn wǝ silǝr samawi ⱪoxunlarning Sǝrdari bolƣan Pǝrwǝrdigarning Meni ǝwǝtkǝnlikini bilisilǝr;
12 Olúwa yóò sì jogún Juda ìní rẹ̀, ni ilẹ̀ mímọ́, yóò sì tún yan Jerusalẹmu.
xuningdǝk Pǝrwǝrdigar Yǝⱨudani Ɵzining «muⱪǝddǝs zemini»da nesiwisi boluxⱪa miras ⱪilidu wǝ yǝnǝ Yerusalemni talliwalidu.
13 Ẹ̀ dákẹ́, gbogbo ẹran-ara níwájú Olúwa: nítorí a jí i láti ibùgbé mímọ́ rẹ̀ wá.”
Barliⱪ ǝt igiliri Pǝrwǝrdigar aldida süküt ⱪilsun! Qünki U Ɵzining muⱪǝddǝs makanidin ⱪozƣaldi!»

< Zechariah 2 >