< Zechariah 2 >

1 Mó si tún gbé ojú mi, sókè, mo sì wò, sì kíyèsi i, ọkùnrin kan ti o mú okùn ìwọ̀n lọ́wọ́ rẹ̀.
Mi-am ridicat ochii din nou şi am privit şi iată, un om cu o frânghie de măsurat în mâna lui.
2 Mo sí wí pé, “Níbo ni ìwọ ń lọ?” O sí wí fún mí pé, “Láti wọn Jerusalẹmu, láti rí iye ìbú rẹ̀, àti iye gígùn rẹ̀.”
Atunci am spus: Unde mergi? Şi el mi-a zis: Să măsor Ierusalimul, să văd care este lăţimea lui şi care este lungimea lui.
3 Sì kíyèsi i, angẹli tí ó ń bá mi sọ̀rọ̀ jáde lọ, angẹli mìíràn si jáde lọ pàdé rẹ̀.
Şi, iată, îngerul care vorbea cu mine a ieşit şi un alt înger a ieşit să îl întâlnească,
4 Ó si wí fún un pé, “Sáré, sọ fún ọ̀dọ́mọkùnrin yìí wí pé, ‘A ó gbé inú Jerusalẹmu bi ìlú ti kò ní odi, nítorí ọ̀pọ̀ ènìyàn àti ohun ọ̀sìn inú rẹ̀.
Şi i-a zis: Aleargă, vorbeşte acestui tânăr, spunând: Ierusalimul va fi locuit ca oraşe fără ziduri, din cauza mulţimii oamenilor şi a vitelor din el;
5 Olúwa wí pé: Èmi ó sì jẹ́ odi iná fún un yíká, èmi ó sì jẹ́ ògo láàrín rẹ̀.’
Fiindcă eu, spune DOMNUL, îi voi fi un zid de foc de jur împrejur şi voi fi glorie în mijlocul lui.
6 “Wá! Wá! Sá kúrò ni ilẹ̀ àríwá,” ni Olúwa wí, “nítorí pé bí afẹ́fẹ́ mẹ́rin ọ̀run ni mo tú yín káàkiri,” ni Olúwa wí.
Hei, hei! ieşiţi şi fugiţi din ţara nordului, spune DOMNUL, pentru că v-am împrăştiat ca pe cele patru vânturi ale cerului, spune DOMNUL.
7 “Gbà ara rẹ̀ sílẹ̀, ìwọ Sioni, ìwọ tí ó ń bà ọmọbìnrin Babeli gbé.”
Eliberează-te, Sioane, care locuieşti cu fiica Babilonului!
8 Nítorí báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Lẹ́yìn ògo rẹ̀ ni a ti rán mi sí àwọn orílẹ̀-èdè tí ń kó yin: nítorí ẹni tí ó tọ́ yin, ó tọ́ ọmọ ojú rẹ̀.
Pentru că astfel spune DOMNUL oştirilor: După glorie m-a trimis el la naţiunile care v-au prădat, pentru că cine se atinge de voi se atinge de lumina ochiului său.
9 Nítorí kíyèsi i, èmi ó gbọn ọwọ́ mi sí orí wọn, wọn yóò sì jẹ́ ìkógun fún ìránṣẹ́ wọn: ẹ̀yin yóò sì mọ̀ pé, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni ó rán mi.
Pentru că, iată, eu îmi voi scutura mâna peste ele şi vor ajunge o pradă servitorilor lor; şi veţi cunoaşte că DOMNUL oştirilor m-a trimis.
10 “Kọrin kí o sì yọ̀, ìwọ ọmọbìnrin Sioni. Nítorí èmi ń bọ̀ àti pé èmi yóò sì gbé àárín rẹ,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Cântă şi bucură-te, fiică a Sionului, pentru că, iată, eu vin şi voi locui în mijlocul tău, spune DOMNUL.
11 “Ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè ni yóò dàpọ̀ mọ́ Olúwa ní ọjọ́ náà, wọn yóò sì di ènìyàn mi, èmi yóò sì gbé àárín rẹ, ìwọ yóò sì mọ̀ pé, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni ó rán mi sí ọ.
Şi multe naţiuni se vor alătura DOMNULUI în acea zi şi vor fi poporul meu; şi eu voi locui în mijlocul tău şi vei cunoaşte că DOMNUL oştirilor m-a trimis la tine.
12 Olúwa yóò sì jogún Juda ìní rẹ̀, ni ilẹ̀ mímọ́, yóò sì tún yan Jerusalẹmu.
Şi DOMNUL va moşteni pe Iuda, partea lui în ţara sfântă; şi din nou va alege Ierusalimul.
13 Ẹ̀ dákẹ́, gbogbo ẹran-ara níwájú Olúwa: nítorí a jí i láti ibùgbé mímọ́ rẹ̀ wá.”
Să tacă toată făptura înaintea DOMNULUI, pentru că el s-a ridicat din locuinţa lui sfântă.

< Zechariah 2 >