< Zechariah 2 >

1 Mó si tún gbé ojú mi, sókè, mo sì wò, sì kíyèsi i, ọkùnrin kan ti o mú okùn ìwọ̀n lọ́wọ́ rẹ̀.
Ngaphakamisa amehlo, phambi kwami kwakulomuntu ophethe intambo yokulinganisa!
2 Mo sí wí pé, “Níbo ni ìwọ ń lọ?” O sí wí fún mí pé, “Láti wọn Jerusalẹmu, láti rí iye ìbú rẹ̀, àti iye gígùn rẹ̀.”
Ngabuza ngathi, “Uya ngaphi na?” Wangiphendula wathi, “Ngiyalinganisa iJerusalema, ukubona ukuthi ibanzi njalo inde kanganani.”
3 Sì kíyèsi i, angẹli tí ó ń bá mi sọ̀rọ̀ jáde lọ, angẹli mìíràn si jáde lọ pàdé rẹ̀.
Ingilosi leyo eyayikhuluma lami yasisuka, kweza enye ingilosi iyihlangabeza
4 Ó si wí fún un pé, “Sáré, sọ fún ọ̀dọ́mọkùnrin yìí wí pé, ‘A ó gbé inú Jerusalẹmu bi ìlú ti kò ní odi, nítorí ọ̀pọ̀ ènìyàn àti ohun ọ̀sìn inú rẹ̀.
yathi kuyo: “Gijima utshele ijaha leliyana uthi, ‘IJerusalema izakuba lidolobho elingelamiduli ngenxa yobunengi babantu lezifuyo phakathi kwalo.
5 Olúwa wí pé: Èmi ó sì jẹ́ odi iná fún un yíká, èmi ó sì jẹ́ ògo láàrín rẹ̀.’
Mina ngokwami ngizakuba ngumduli womlilo olizungezileyo,’ kutsho uThixo, ‘njalo ngizakuba yinkazimulo ngaphakathi kwalo.’
6 “Wá! Wá! Sá kúrò ni ilẹ̀ àríwá,” ni Olúwa wí, “nítorí pé bí afẹ́fẹ́ mẹ́rin ọ̀run ni mo tú yín káàkiri,” ni Olúwa wí.
Wozani! Wozani! Balekani kulelolizwe lasenyakatho,” kutsho uThixo, “ngoba ngilichithachithile kuyo yonke imimoya yomine yezulu,” kutsho uThixo.
7 “Gbà ara rẹ̀ sílẹ̀, ìwọ Sioni, ìwọ tí ó ń bà ọmọbìnrin Babeli gbé.”
“Woza, yeyi wena Ziyoni! Balekani lina elihlala eNdodakazini yaseBhabhiloni!”
8 Nítorí báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Lẹ́yìn ògo rẹ̀ ni a ti rán mi sí àwọn orílẹ̀-èdè tí ń kó yin: nítorí ẹni tí ó tọ́ yin, ó tọ́ ọmọ ojú rẹ̀.
Ngoba lokhu kutshiwo nguThixo uSomandla, uthi: “Ngemva kokuba Olodumo esengithumile ukumelana lezizwe eziliphangileyo ngoba loba ngubani oke alithinte lina uthinta igugu lakhe
9 Nítorí kíyèsi i, èmi ó gbọn ọwọ́ mi sí orí wọn, wọn yóò sì jẹ́ ìkógun fún ìránṣẹ́ wọn: ẹ̀yin yóò sì mọ̀ pé, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni ó rán mi.
ngempela ngizaphakamisela isandla sami kubo ukuze izigqili zabo zibaphange. Lapho-ke lizakwazi ukuthi uThixo uSomandla nguye ongithumileyo.
10 “Kọrin kí o sì yọ̀, ìwọ ọmọbìnrin Sioni. Nítorí èmi ń bọ̀ àti pé èmi yóò sì gbé àárín rẹ,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Memeza ujabule, we Ndodakazi yaseZiyoni. Ngoba ngiyeza, njalo ngizahlala phakathi kwenu,” kutsho uThixo.
11 “Ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè ni yóò dàpọ̀ mọ́ Olúwa ní ọjọ́ náà, wọn yóò sì di ènìyàn mi, èmi yóò sì gbé àárín rẹ, ìwọ yóò sì mọ̀ pé, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni ó rán mi sí ọ.
“Izizwe ezinengi zizahlanganiswa loThixo ngalelolanga njalo zizakuba ngabantu bami. Ngizahlala phakathi kwenu njalo lizakwazi ukuthi uThixo uSomandla ungithumile kini.
12 Olúwa yóò sì jogún Juda ìní rẹ̀, ni ilẹ̀ mímọ́, yóò sì tún yan Jerusalẹmu.
UThixo uzamthatha uJuda njengelifa abe yisabelo sakhe elizweni elingcwele njalo uzaphinda ayikhethe iJerusalema.
13 Ẹ̀ dákẹ́, gbogbo ẹran-ara níwájú Olúwa: nítorí a jí i láti ibùgbé mímọ́ rẹ̀ wá.”
Pholani lithule phambi kukaThixo, bantu lonke, ngoba uphakamile waphuma endaweni yakhe engcwele.”

< Zechariah 2 >