< Zechariah 14 >

1 Kíyèsi i, ọjọ́ Olúwa ń bọ̀, a ó sì pín ìkógun rẹ̀ láàrín rẹ̀.
Mana, Perwerdigargha xas kün kélidu; [u küni] arangdin mal-mülküng bulang-talang qilinip bölüshüwélinidu.
2 Nítorí èmi ó kó gbogbo orílẹ̀-èdè jọ sí Jerusalẹmu fún ogun; a ó sì ko ìlú náà, a ó sì kó àwọn ilé, a ó sì ba àwọn obìnrin jẹ́, ààbọ̀ ìlú náà yóò lọ sí ìgbèkùn, a kì yóò sì gé ìyókù àwọn ènìyàn náà kúrò ni ìlú náà.
Men barliq ellerni Yérusalémgha jeng qilishqa yighimen; sheher ishghal qilinidu, öyler bulang-talang qilinip, qiz-ayallar ayagh-asti qilinidu; sheherning yérimi esirge chüshüp sürgün qilinidu; tirik qalghan xelq sheherdin élip kétilmeydu.
3 Nígbà náà ni Olúwa yóò jáde lọ, yóò sì bá àwọn orílẹ̀-èdè náà jà, gẹ́gẹ́ bí í ti ìjà ní ọjọ́ ogun.
Andin Perwerdigar chiqip shu eller bilen urushidu; U Uning jeng qilghan künidikidek urushidu.
4 Ẹsẹ̀ rẹ̀ yóò sì dúró ni ọjọ́ náà lórí òkè Olifi, tí ó wà níwájú Jerusalẹmu ni ìlà-oòrùn, òkè Olifi yóò sì là á sí méjì, sí ìhà ìlà-oòrùn àti ìhà ìwọ̀-oòrùn, àfonífojì ńlá ńlá yóò wà: ìdajì òkè náà yóò sì ṣí síhà àríwá, àti ìdajì rẹ̀ síhà gúúsù.
Uning putliri shu küni Yérusalémning sherqiy teripining eng aldi bolghan Zeytun téghida turidu; shuning bilen Zeytun téghi otturidin sherq we gherb terepke yérilidu; zor yoghan bir jilgha peyda bolidu; taghning yérimi shimal terepke, yérimi jenub terepke yötkilidu.
5 Ẹ̀yin ó sì sá sí àfonífojì àwọn òkè mi, nítorí pé àfonífojì òkè náà yóò dé Aseli: nítòótọ́, ẹ̀yin ó sá bí ẹ tí sá fún ìmìmì-ilẹ̀ ni ọjọ́ Ussiah ọba Juda: Olúwa Ọlọ́run mi yóò sì wá, àti gbogbo àwọn Ẹni mímọ́ pẹ̀lú rẹ̀.
We siler Méning taghlirimning del mushu jilghisi bilen qachisiler; chünki taghlarning jilghisi Azelgiche baridu; siler Yehuda padishahi Uzziyaning künliride bolghan yer tewreshte qachqininglardek qachisiler. Andin Perwerdigar Xudayim kélidu; hemde Sen bilen barliq «muqeddes bolghuchilar»mu kélidu!
6 Yóò sì ṣe ni ọjọ́ náà, ìmọ́lẹ̀ kì yóò mọ́, bẹ́ẹ̀ ni kì yóò ṣókùnkùn.
Shu küni shundaq boliduki, nur toxtap qalidu; parlaq yultuzlarmu qarangghuliship kétidu;
7 Ṣùgbọ́n yóò jẹ́ ọjọ́ kan mímọ́ fún Olúwa, kì í ṣe ọ̀sán, kì í ṣe òru; ṣùgbọ́n yóò ṣe pé, ni àṣálẹ́ ìmọ́lẹ̀ yóò wà.
Biraq u Perwerdigargha melum bolghan alahide bir kün, ya kéche ya kündüz bolmaydu; shundaq emelge ashuruliduki, kech kirgende, alem yorutulidu.
8 Yóò sì ṣe ní ọjọ́ náà, omi ìyè yóò tí Jerusalẹmu sàn lọ; ìdajì wọn síhà Òkun ìlà-oòrùn, àti ìdajì wọn síhà okùn ẹ̀yìn: nígbà ẹ̀rùn àti nígbà òtútù ni yóò rí bẹ́ẹ̀.
Shu küni shundaq boliduki, hayatliq suliri Yérusalémdin éqip chiqidu; ularning yérimi sherqiy déngizgha, yérimi gherbiy déngizgha qarap aqidu; yazda we qishta shundaq bolidu.
9 Olúwa yóò sì jẹ ọba lórí gbogbo ayé; ni ọjọ́ náà ni Olúwa kan yóò wa orúkọ rẹ̀ nìkan náà ni orúkọ.
Perwerdigar pütkül yer yüzi üstide padishah bolidu; shu küni peqet bir «Perwerdigar» bolidu, [yer yüzide] birdinbir Uningla nami bolidu.
10 A ó yí gbogbo ilẹ̀ padà bi pẹ̀tẹ́lẹ̀ kan láti Geba dé Rimoni lápá gúúsù Jerusalẹmu: yóò di bí aginjù, ṣùgbọ́n a ó sì gbé Jerusalẹmu sókè, yóò sì gbe ipò rẹ̀, láti ibodè Benjamini títí dé ibi ibodè èkínní, dé ibodè igun nì, àti láti ilé ìṣọ́ Hananeli dé ibi ìfúntí wáìnì ọba.
Gébadin Yérusalémning jenubidiki Rimmon’ghiche bolghan pütün zémin «Arabah»dek tüzlenglikke aylandurulidu; Yérusalém bolsa «Binyamin derwazisi»din «Birinchi derwaza»ghiche we yene «Burjek derwazisi»ghiche, «Hananiyelning munari»din padishahning sharab kölcheklirigiche yuqiri kötürülidu, lékin sheher yenila öz jayida shu péti turidu;
11 Ènìyàn yóò sì máa gbé ibẹ̀, kì yóò sì sí ìparun mọ́; ṣùgbọ́n a ó máa gbé Jerusalẹmu láìléwu.
Ademler yene uningda turidu. «Halak permani» yene héch chüshürülmeydu; Yérusalém xatirjemlikte turidu.
12 Èyí ni yóò sì jẹ́ ààrùn tí Olúwa yóò fi kọlu gbogbo àwọn ènìyàn ti ó tí ba Jerusalẹmu jà; ẹran-ara wọn yóò rù nígbà tí wọn dúró ni ẹsẹ̀ wọn, ojú wọn yóò sì rà ni ihò wọn, ahọ́n wọn yóò sì bàjẹ́ ni ẹnu wọn.
We Perwerdigar Yérusalémgha jeng qilghan barliq ellerni urushqa ishletken waba shundaq boliduki, ular öre bolsila göshliri chirip kétidu; közliri chanaqlirida chirip kétidu; tilliri aghzida chirip kétidu.
13 Yóò sì ṣe ni ọjọ́ náà, ìrọ́kẹ̀kẹ̀ ńlá láti ọ̀dọ̀ Olúwa wá yóò wà láàrín wọn; wọn ó sì di ọwọ́ ara wọn mú, ọwọ́ èkínní yóò sì dìde sì ọwọ́ èkejì rẹ̀.
Shu küni shundaq boliduki, ularning arisigha Perwerdigardin zor bir alaqzadilik chüshidu; ular herbiri öz yéqinining qolini tutushidu, herbirining qoli yéqinining qoligha qarshi kötürülidu.
14 Juda pẹ̀lú yóò sì jà ni Jerusalẹmu: ọrọ̀ gbogbo àwọn kèfèrí tí ó wà káàkiri ni a ó sì kójọ, wúrà àti fàdákà, àti aṣọ, ní ọ̀pọ̀lọpọ̀.
Yehudamu Yérusalémda jeng qilidu; etrapidiki barliq ellerning mal-mülükliri jem qilip yighilidu — san-sanaqsiz altun-kümüsh we kiyim-kéchekler bolidu.
15 Bẹ́ẹ̀ ni ààrùn ẹṣin, ìbáaka, ìbákasẹ, àti tí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, yóò sì wà, àti gbogbo ẹranko tí ń bẹ nínú àgọ́.
At, qéchir, töge, éshek, shundaqla ularning bargahlirida bolghan barliq mal-waranlar üstige chüshken waba yuqiriqi wabagha oxshash bolidu.
16 Yóò sì ṣe, olúkúlùkù ẹni tí o kù nínú gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí ó dìde sí Jerusalẹmu yóò máa gòkè lọ lọ́dọọdún láti sìn ọba, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, àti láti ṣe àjọyọ̀ àsè àgọ́ náà.
Shundaq emelge ashuruliduki, Yérusalémgha jeng qilishqa kelgen hemme ellerdin barliq tirik qalghanlar her yili Yérusalémgha, padishahqa, yeni samawi qoshunlarning Serdari bolghan Perwerdigargha ibadet qilishqa we «kepiler héyti»ni tebrikleshke chiqidu.
17 Yóò sì ṣe, ẹnikẹ́ni tí kì yóò gòkè wá nínú gbogbo ìdílé ayé sí Jerusalẹmu láti sín ọba, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, òjò kì yóò rọ̀ fún wọn.
Shundaq boliduki, yer yüzidiki qowm-jemetlerdin padishahqa, yeni samawi qoshunlarning Serdari bolghan Perwerdigargha ibadetke chiqmighanlar bolsa, emdi ularning üstige yamghur yaghmaydu.
18 Bí ìdílé Ejibiti kò bá sì gòkè lọ, tí wọn kò sì wá, fi ara wọn hàn tí wọn kò ní òjò; ààrùn náà yóò wà, tí Olúwa yóò fi kọlù àwọn kèfèrí tí kò gòkè wá láti ṣe àjọyọ̀ àsè àgọ́ náà.
Misir jemeti chiqip hazir bolmisa, ularghimu yamghur bolmaydu; biraq Perwerdigar «kepiler héyti»ni tebrikleshke chiqmaydighan barliq eller üstige chüshüridighan waba ularghimu chüshürülidu.
19 Èyí ni yóò sì jẹ́ ìyà Ejibiti, àti ìyà gbogbo orílẹ̀-èdè tí kò gòkè wá láti pa àsè àgọ́ mọ́.
Bu Misirning jazasi, shundaqla «kepiler héyti»ni tebrikleshke chiqmaydighan barliq ellerning jazasi bolidu.
20 Ní ọjọ́ náà ni “mímọ́ sí Olúwa” yóò wà lára ṣaworo ẹṣin: àti àwọn ìkòkò ni ilé Olúwa yóò sì dàbí àwọn ọpọ́n tí ń bẹ níwájú pẹpẹ.
Shu küni atlarning qongghuraqliri üstige «Perwerdigargha atilip pak-muqeddes bolsun!» dep yézilidu; Perwerdigarning öyidiki barliq qacha-quchilarmu qurban’gah aldidiki qachilargha oxshash hésablinidu;
21 Nítòótọ́, gbogbo ìkòkò ni Jerusalẹmu àti ni Juda yóò jẹ́ mímọ́ sí Olúwa àwọn ọmọ-ogun: àti gbogbo àwọn tí ń rú ẹbọ yóò wá, wọn ó sì mú ìkòkò díẹ̀, wọn ó sì bọ ẹran wọn nínú rẹ̀, ni ọjọ́ náà ni àwọn Kenaani kò ní sí mọ́ ni ilé Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
Yérusalémdiki we Yehudadiki barliq qacha-quchilarmu Perwerdigargha atilip pak-muqeddes bolidu; qurbanliq qilghuchilar kélip ularni élip qurbanliq göshlirini pishuridu; shu küni samawi qoshunlarning Serdari bolghan Perwerdigarning öyide «qanaanliq-sodiger» ikkinchi bolmaydu.

< Zechariah 14 >