< Zechariah 14 >
1 Kíyèsi i, ọjọ́ Olúwa ń bọ̀, a ó sì pín ìkógun rẹ̀ láàrín rẹ̀.
Eso amoga Hina Gode da osobo bagade dunuma fofada: musa: fimu, da gadenesa. Amo esoga, Yelusaleme ea liligi huluane doagala: le samogei dagoi ba: mu. Amola dilia ba: ma: ne, dilia ha lai dunu da amo liligi momogili lamu.
2 Nítorí èmi ó kó gbogbo orílẹ̀-èdè jọ sí Jerusalẹmu fún ogun; a ó sì ko ìlú náà, a ó sì kó àwọn ilé, a ó sì ba àwọn obìnrin jẹ́, ààbọ̀ ìlú náà yóò lọ sí ìgbèkùn, a kì yóò sì gé ìyókù àwọn ènìyàn náà kúrò ni ìlú náà.
Hina Gode da fifi asi gala huluane gagadole, Yelusalemema doagala: musa: oule misunu. Ilia da Yelusaleme doagala: le lamu, diasu huluane ilia liligi samogele lamu amola uda huluane hiougili lale wadela: lesimu. Ilia da dunu dogoa mogili, mugululi oule masa: ne gagumu. Be eno dogoa mogili da amogawi esalumu.
3 Nígbà náà ni Olúwa yóò jáde lọ, yóò sì bá àwọn orílẹ̀-èdè náà jà, gẹ́gẹ́ bí í ti ìjà ní ọjọ́ ogun.
Amasea, Hina Gode da Ea musa: gegesu hou defele, asili, amo fifi asi gala ilima gegemu.
4 Ẹsẹ̀ rẹ̀ yóò sì dúró ni ọjọ́ náà lórí òkè Olifi, tí ó wà níwájú Jerusalẹmu ni ìlà-oòrùn, òkè Olifi yóò sì là á sí méjì, sí ìhà ìlà-oòrùn àti ìhà ìwọ̀-oòrùn, àfonífojì ńlá ńlá yóò wà: ìdajì òkè náà yóò sì ṣí síhà àríwá, àti ìdajì rẹ̀ síhà gúúsù.
Amo esoha, E da Olife Goumi (Yelusaleme ea guma: dini la: idi diala) amo da: iya lelumu. Amasea, Olife Goumi da mogoa odahidale, gusudili asili, guma: dini sa: ili, fago bagadedafa dogoa dialebe ba: mu. Goumi mogi na: iyado da ga (south) amoga gasi gamu. Amola na: iyado da ga (north) amoga gasi gamu.
5 Ẹ̀yin ó sì sá sí àfonífojì àwọn òkè mi, nítorí pé àfonífojì òkè náà yóò dé Aseli: nítòótọ́, ẹ̀yin ó sá bí ẹ tí sá fún ìmìmì-ilẹ̀ ni ọjọ́ Ussiah ọba Juda: Olúwa Ọlọ́run mi yóò sì wá, àti gbogbo àwọn Ẹni mímọ́ pẹ̀lú rẹ̀.
Dilia da goumi amo mogisa fago hamoi, amoga hobeale masa! Yuda hina bagade Asia ea ouligibi esoha, bebeda: nima bagade da osobo fogoloba, dilia aowalali da hobea: i dagoi. Amo defele, dilia amola da goumi odahida: i amo esohaga hobeama. Na Hina Gode da amo esoha misunu. Amola E da Ea a: igele dunu huluane sigi misunu.
6 Yóò sì ṣe ni ọjọ́ náà, ìmọ́lẹ̀ kì yóò mọ́, bẹ́ẹ̀ ni kì yóò ṣókùnkùn.
Amo eso da doaga: sea, anegagi amola mugene oubi baeya su da bu mae misa: ne, asi dagoi ba: mu.
7 Ṣùgbọ́n yóò jẹ́ ọjọ́ kan mímọ́ fún Olúwa, kì í ṣe ọ̀sán, kì í ṣe òru; ṣùgbọ́n yóò ṣe pé, ni àṣálẹ́ ìmọ́lẹ̀ yóò wà.
Amola gasimigi da bu hame ba: mu. Eso hadigi fawane ba: mu. Gasi ilegei amolawane amo ganodini da hadigi fawane ba: mu. Be Hina Gode, Hi fawane da amo misunu hou ea eso ilegei dawa:
8 Yóò sì ṣe ní ọjọ́ náà, omi ìyè yóò tí Jerusalẹmu sàn lọ; ìdajì wọn síhà Òkun ìlà-oòrùn, àti ìdajì wọn síhà okùn ẹ̀yìn: nígbà ẹ̀rùn àti nígbà òtútù ni yóò rí bẹ́ẹ̀.
Amo eso da doaga: sea, nasegagi hano da Yelusaleme amoga dalebe ba: mu. Amo hano da dogoa mogili, na: iyado afae da Bogoi Hano Wayabo amoga dalebe ba: mu amola na: iyado eno da Medidela: inia Hano Wayabo Bagadega dalebe ba: mu. Amo hano da ode huluane amoga dalebe ba: mu - gibu dabe oubiga amola hafoga: i oubiga, mae fisili dalebe ba: mu.
9 Olúwa yóò sì jẹ ọba lórí gbogbo ayé; ni ọjọ́ náà ni Olúwa kan yóò wa orúkọ rẹ̀ nìkan náà ni orúkọ.
Amasea, Hina Gode da osobo bagade fifi asi gala ilima Hina Bagade esalebe ba: mu. Dunu huluanedafa da E da Godedafa dawa: beba: le, Ema nodone sia: ne gadomu amola Ema Godedafa Dio asulimu.
10 A ó yí gbogbo ilẹ̀ padà bi pẹ̀tẹ́lẹ̀ kan láti Geba dé Rimoni lápá gúúsù Jerusalẹmu: yóò di bí aginjù, ṣùgbọ́n a ó sì gbé Jerusalẹmu sókè, yóò sì gbe ipò rẹ̀, láti ibodè Benjamini títí dé ibi ibodè èkínní, dé ibodè igun nì, àti láti ilé ìṣọ́ Hananeli dé ibi ìfúntí wáìnì ọba.
Soge amo da Giba ga (north) gala asili Limone ga (south) gala, amo dibiga huluane da umi agoane hamoi dagoi ba: mu. Yelusaleme da goumi agoane, amo umi soge amoga gado heda: lebe ba: mu. Yelusaleme moilai bai bagade sogebi da Bediamini Logo Ga: suga asili Hegomai Logo Ga: su (amogawi eno Logo Ga: su da musa: galu) amoga masunu. Amola Hana: niele Diasu Gagagula Heda: i amoga asili, hina bagade dunu ilia Waini Hano Banesu amoga doaga: mu.
11 Ènìyàn yóò sì máa gbé ibẹ̀, kì yóò sì sí ìparun mọ́; ṣùgbọ́n a ó máa gbé Jerusalẹmu láìléwu.
Dunu da Yelusaleme ganodini gaga: iwane esalumu. Amola enoga wadela: lesisa: besa: le, ilia bu hame beda: mu.
12 Èyí ni yóò sì jẹ́ ààrùn tí Olúwa yóò fi kọlu gbogbo àwọn ènìyàn ti ó tí ba Jerusalẹmu jà; ẹran-ara wọn yóò rù nígbà tí wọn dúró ni ẹsẹ̀ wọn, ojú wọn yóò sì rà ni ihò wọn, ahọ́n wọn yóò sì bàjẹ́ ni ẹnu wọn.
Hina Gode da fifi asi gala huluane da Yelusalemema gegebe, ilima olo bagadedafa iasimu. Ilia da esaleawane, ilia hu dasai dagoi ba: mu. Ilia si amola ilia gona: su da dasagia: mu.
13 Yóò sì ṣe ni ọjọ́ náà, ìrọ́kẹ̀kẹ̀ ńlá láti ọ̀dọ̀ Olúwa wá yóò wà láàrín wọn; wọn ó sì di ọwọ́ ara wọn mú, ọwọ́ èkínní yóò sì dìde sì ọwọ́ èkejì rẹ̀.
Amo esoha, Hina Gode da ili ededenanesima: ne amola beda: ma: ne hamomu. Amai hamobeba: le, dunu huluane da ema dafulili lela dunu amo gagulaligili, doagala: mu.
14 Juda pẹ̀lú yóò sì jà ni Jerusalẹmu: ọrọ̀ gbogbo àwọn kèfèrí tí ó wà káàkiri ni a ó sì kójọ, wúrà àti fàdákà, àti aṣọ, ní ọ̀pọ̀lọpọ̀.
Yuda dunu da Yelusaleme gaga: ma: ne, gegemu. Ilia da fifi asi gala ilia bagade gagui liligi - gouli, silifa amola abula bagohamedafa - amo ilima doagala: le lamu.
15 Bẹ́ẹ̀ ni ààrùn ẹṣin, ìbáaka, ìbákasẹ, àti tí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, yóò sì wà, àti gbogbo ẹranko tí ń bẹ nínú àgọ́.
Amola ohe fi amo da ha lai dunu ilia fisisu ganodini esala-hosi, miule, ga: mele, dougi - ohe fi huluane ilima olo bagadedafa da madelamu.
16 Yóò sì ṣe, olúkúlùkù ẹni tí o kù nínú gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí ó dìde sí Jerusalẹmu yóò máa gòkè lọ lọ́dọọdún láti sìn ọba, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, àti láti ṣe àjọyọ̀ àsè àgọ́ náà.
Amasea, fifi asi gala amo da Yelusaleme doagala: i, ilia hame bogoi esalebe dunu da ode huluane Yelusaleme moilai bai bagade, Hina Gode Bagadedafa Ema nodone sia: ne gadomusa: , amola Sogega Fasela Diasu Lolo Nasu Gilisisu amoga masunu.
17 Yóò sì ṣe, ẹnikẹ́ni tí kì yóò gòkè wá nínú gbogbo ìdílé ayé sí Jerusalẹmu láti sín ọba, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, òjò kì yóò rọ̀ fún wọn.
Be fifi asi gala afae da Hina Gode Bagadedafa Ema nodone sia: ne gadomusa: masunu higasea, amo fifi asi gala ea sogega gibu da hame sa: imu.
18 Bí ìdílé Ejibiti kò bá sì gòkè lọ, tí wọn kò sì wá, fi ara wọn hàn tí wọn kò ní òjò; ààrùn náà yóò wà, tí Olúwa yóò fi kọlù àwọn kèfèrí tí kò gòkè wá láti ṣe àjọyọ̀ àsè àgọ́ náà.
Idibidi fi dunu da Sogega Fasela Diasu Lolo Nasu Gilisisu amoga masunu higasea, Hina Gode da olo bagade amo E da fifi asi gala huluane amo da masunu hihi ilima iaha, amo ilima iasimu.
19 Èyí ni yóò sì jẹ́ ìyà Ejibiti, àti ìyà gbogbo orílẹ̀-èdè tí kò gòkè wá láti pa àsè àgọ́ mọ́.
Idibidi amola fifi asi gala huluane amo da Sogega Fasela Diasu Lolo Nasu Gilisisu amoga masunu hihi galea, ilia da amo se dabe lamu.
20 Ní ọjọ́ náà ni “mímọ́ sí Olúwa” yóò wà lára ṣaworo ẹṣin: àti àwọn ìkòkò ni ilé Olúwa yóò sì dàbí àwọn ọpọ́n tí ń bẹ níwájú pẹpẹ.
Amo esoha amolawane, ‘belo’ amo da hosi ilia hiougisu efe liligi amoga lala: gi, amoga “Hina Godema Mogili Gagai Dagoi” amane dedei dagoi ba: mu. Amola gobele nasu ofodo amola ofodo oloda ea midadi diala, amo defele hadigi sema hamoi dagoi ba: mu.
21 Nítòótọ́, gbogbo ìkòkò ni Jerusalẹmu àti ni Juda yóò jẹ́ mímọ́ sí Olúwa àwọn ọmọ-ogun: àti gbogbo àwọn tí ń rú ẹbọ yóò wá, wọn ó sì mú ìkòkò díẹ̀, wọn ó sì bọ ẹran wọn nínú rẹ̀, ni ọjọ́ náà ni àwọn Kenaani kò ní sí mọ́ ni ilé Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
Gobele nasu ofodo huluane Yelusaleme amola Yuda soge ganodini diala da Hina Gode Bagadedafa Ema, nodone sia: ne gadomusa: , momodale ligiagai dagoi ba: mu. Dunu amo da gobele salasu iabe, da amo ofodo ilia gobele salasu hu amo gobesu hamomu. Amo eso da doaga: sea, bidiga lasu dunu amola bidiga lama: ne legesu dunu afae da Hina Gode Bagadedafa Ea Debolo Diasu ganodini hame ba: mu. Sia ama dagoi