< Zechariah 12 >

1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀. Ọ̀rọ̀ Olúwa fún Israẹli ni. Olúwa wí, ẹni tí ó na àwọn ọ̀run, tí ó sì fi ìpìlẹ̀ ayé sọlẹ̀, tí ó sì da ẹ̀mí ènìyàn tí ń bẹ ni inú rẹ̀,
Pǝrwǝrdigarning Israil toƣruluⱪ sɵzidin yüklǝngǝn bexarǝt: — Asmanlarni yayƣuqi, yǝrning ulini salƣuqi, adǝmning roⱨini uning iqidǝ Yasiƣuqi Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: —
2 “Kíyèsi í, èmi yóò sọ Jerusalẹmu dí àgọ́ ìwárìrì sí gbogbo ènìyàn yíká, nígbà tí wọn yóò dó ti Juda àti Jerusalẹmu.
Mana, Mǝn Yerusalemni ǝtrapidiki barliⱪ ǝllǝrgǝ kixilǝrni dǝkkǝ-dükkigǝ salidiƣan apⱪur ⱪilimǝn; Yerusalemƣa qüxidiƣan muⱨasirǝ Yǝⱨudaƣimu qüxidu.
3 Ní ọjọ́ náà, nígbà tí gbogbo orílẹ̀-èdè ayé bá parapọ̀ sí i, ni èmi yóò sọ Jerusalẹmu di òkúta ti ko ṣe yí kúrò fún gbogbo ènìyàn, gbogbo àwọn tí ó bá sì fẹ́ yí i ni a ó gé sí wẹ́wẹ́,
Xu küni ǝmǝlgǝ axuruliduki, Mǝn Yerusalemni barliⱪ ǝllǝrgǝ eƣir yük bolƣan tax ⱪilimǝn; kim uni ɵzigǝ yüklisǝ yarilanmay ⱪalmaydu; yǝr yüzidiki barliⱪ ǝllǝr uningƣa jǝng ⱪilixⱪa yiƣilidu.
4 ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí, “Ni èmi yóò fi ìdágìrì lu gbogbo ẹṣin, àti fi òmùgọ̀ kọlu ẹni tí ń gun un; èmi yóò sì ṣí ojú mi sí ilé Juda, èmi yóò sì bu ìfọ́jú lu gbogbo ẹṣin tí orílẹ̀-èdè.
Xu küni Mǝn ⱨǝmmǝ atlarni sarasimigǝ selip, atliⱪlarni sarang ⱪilip urimǝn; biraⱪ Yǝⱨuda jǝmǝtini kɵzümdǝ tutimǝn; ǝllǝrdiki ⱨǝrbir atni bolsa korluⱪ bilǝn uruwetimǝn.
5 Àti àwọn baálẹ̀ Juda yóò sì wí ni ọkàn wọn pé, ‘Àwọn ara Jerusalẹmu ni agbára mi nípa Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni Ọlọ́run wọn.’
Xuning bilǝn Yǝⱨudaning yolbaxqiliri kɵnglidǝ: «Yerusalemda turuwatⱪanlar samawi ⱪoxunlarning Sǝrdari bolƣan Pǝrwǝrdigar, ularning Hudasi arⱪiliⱪ manga küq bolidu» dǝydu.
6 “Ní ọjọ́ náà, ni èmi yóò ṣe àwọn baálẹ̀ Juda bí ààrò iná kan láàrín igi, àti bi ẹ̀fúùfù iná láàrín ìtí; wọn yóò sì jẹ gbogbo àwọn ènìyàn run yíká lápá ọ̀tún àti lápá òsì, a ó sì tún máa gbé inú Jerusalẹmu ní ipò rẹ̀.
Xu küni Mǝn Yǝⱨudaning yolbaxqilirini otunlar arisidiki otdandǝk, ɵnqilǝr arisidiki mǝx’ǝldǝk ⱪilimǝn; ular ǝtrapidiki barliⱪ ǝllǝrni, yǝni ong wǝ sol tǝripidikilǝrni yǝwetidu; Yerusalemdikilǝr yǝnǝ ɵz jayida, yǝni Yerusalem xǝⱨiridǝ turidiƣan bolidu.
7 “Olúwa pẹ̀lú yóò kọ́ tètè gba àgọ́ Juda là ná, kí ògo ilé Dafidi àti ògo àwọn ara Jerusalẹmu má ba gbé ara wọn ga sí Juda.
Pǝrwǝrdigar awwal Yǝⱨudaning qedirlirini ⱪutⱪuzidu; sǝwǝbi — Dawut jǝmǝtining xan-xǝripi ⱨǝm Yerusalemda turuwatⱪanlarning xan-xǝripi Yǝⱨudaningkidin uluƣlanmasliⱪi üqündur.
8 Ní ọjọ́ náà ni Olúwa yóò dáàbò bò àwọn tí ń gbé Jerusalẹmu; ẹni tí ó bá sì ṣe àìlera nínú wọn ní ọjọ́ náà, yóò dàbí Dafidi; ilé Dafidi yóò sì dàbí Ọlọ́run, bí angẹli Olúwa níwájú wọn.
Xu küni Pǝrwǝrdigar Yerusalemda turuwatⱪanlarni ⱪoƣdaydu; ularning arisidiki ǝlǝngxip ⱪalƣanlarmu xu küni Dawuttǝk palwan bolidu; Dawut jǝmǝti bolsa Hudadǝk, yǝni ularning aldidiki Pǝrwǝrdigarning Pǝrixtisidǝk küqlük bolidu.
9 Yóò sì ṣe ni ọjọ́ náà, èmi yóò wá láti pa gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè run tí ó wá kọjú ìjà sí Jerusalẹmu.”
Xu küni ǝmǝlgǝ axuruliduki, Yerusalemƣa jǝng ⱪilixⱪa kǝlgǝn barliⱪ ǝllǝrni ⱨalak ⱪilixⱪa kiriximǝn.
10 “Èmi ó sì tu ẹ̀mí oore-ọ̀fẹ́ àti ẹ̀bẹ̀ sórí ilé Dafidi àti sórí Jerusalẹmu, wọn ó sì máa wo ẹni tí wọn tí gún ni ọ̀kọ̀, wọn ó sì máa ṣọ̀fọ̀ rẹ̀, bí ẹnìkan ti ń ṣọ̀fọ̀ fún ọmọ rẹ̀ kan ṣoṣo àti gẹ́gẹ́ bí ènìyàn tí wọn yóò sì wà ni ìbànújẹ́, bí ẹni tí ń banújẹ́ fún àkọ́bí rẹ̀.
Wǝ Mǝn Dawut jǝmǝti wǝ Yerusalemda turuwatⱪanlar üstigǝ xapaǝt yǝtküzgüqi wǝ xapaǝt tiligüqi Roⱨni ⱪuyimǝn; xuning bilǝn ular ɵzliri sanjip ɵltürgǝn Manga yǝnǝ ⱪaraydu; birsining tunji oƣli üqün matǝm tutup yiƣa-zar kɵtürgǝndǝk ular Uning üqün yiƣa-zar kɵtüridu; yǝkkǝ-yeganǝ oƣlidin juda bolƣuqining dǝrd-ǝlǝm tartⱪinidǝk ular uning üqün dǝrd-ǝlǝm tartidu.
11 Ní ọjọ́ náà ni ẹkún, ńlá ńlá yóò wà ni Jerusalẹmu, gẹ́gẹ́ bí ọ̀fọ̀ Hadadi Rimoni ni àfonífojì Megido.
Xu küni Yerusalemda ƣayǝt zor yiƣa-zar kɵtürülidu, u Mǝgiddo jilƣisidiki «Hadad-Rimmon»da kɵtürülgǝn yiƣa-zardǝk bolidu.
12 Ilẹ̀ náà yóò ṣọ̀fọ̀, ìdílé, kọ̀ọ̀kan fun ara rẹ, lọ́tọ̀ọ̀tọ̀; ìdílé Dafidi lọ́tọ̀; àti àwọn aya wọn lọ́tọ̀; ìdílé Natani lọ́tọ̀, àti àwọn aya wọn lọ́tọ́.
Zemin yiƣa-zar kɵtüridu; ⱨǝrbir ailǝ ayrim ⱨalda yiƣa-zar kɵtüridu. Dawut jǝmǝti ayrim ⱨalda, ularning ayalliri ayrim ⱨalda, Natan jǝmǝti ayrim ⱨalda, ularning ayalliri ayrim ⱨalda;
13 Ìdílé Lefi lọ́tọ̀, àti àwọn aya wọn lọ́tọ̀; ìdílé Ṣimei lọ́tọ̀, àti àwọn aya wọn lọ́tọ̀.
Lawiy jǝmǝti ayrim ⱨalda, ularning ayalliri ayrim ⱨalda; Ximǝy jǝmǝti ayrim ⱨalda, ularning ayalliri ayrim ⱨalda;
14 Gbogbo àwọn ìdílé tí o kù, ìdílé, ìdílé, lọ́tọ̀ọ̀tọ̀, àti àwọn aya wọn lọ́tọ̀ọ̀tọ̀.
barliⱪ tirik ⱪalƣan aililǝr, yǝni ⱨǝrbir ailǝ ayrim-ayrim ⱨalda wǝ ularning ayalliri ayrim ⱨalda yiƣa-zar kɵtüridu.

< Zechariah 12 >