< Zechariah 10 >

1 Ẹ béèrè òjò nígbà àrọ̀kúrò ni ọwọ́ Olúwa; Olúwa tí o dá mọ̀nàmọ́ná, tí ó sì fi ọ̀pọ̀ òjò fún ènìyàn, fún olúkúlùkù koríko ní pápá.
İlkbaharda RAB'den yağmur dileyin. O'dur yağmur bulutlarını oluşturan. İnsanlara yağmur sağanakları Ve herkese tarlada ot verir.
2 Nítorí àwọn òrìṣà tí sọ̀rọ̀ asán, àwọn aláfọ̀ṣẹ sì tí rí èké, wọn sì tí rọ àlá èké; wọ́n ń tu ni nínú lásán, nítorí náà àwọn ènìyàn náà ṣáko lọ bí àgùntàn, a ṣẹ wọn níṣẹ̀ẹ́, nítorí Olùṣọ́-àgùntàn kò sí.
Oysa aile putlarından alınan yanıtlar boştur, Falcılar yalan görümler görür Ve gerçek yanı olmayan düşler anlatarak Boşuna avuturlar. Bu yüzden halk sürü gibi dağınık, Sıkıntı çekiyor, çünkü çoban yok.
3 “Ìbínú mi ru sí àwọn darandaran, èmi o sì jẹ àwọn olórí ní yà nítorí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti bẹ agbo rẹ̀, ilé Juda wò, yóò sì fi wọn ṣe ẹṣin rẹ̀ dáradára ní ogun.
RAB şöyle diyor: “Öfkem çobanlara karşı alevlendi, Önderleri cezalandıracağım. Her Şeye Egemen RAB kendi sürüsünü, Yahuda halkını kayıracak. Görkemli savaş atı gibi yapacak onları.
4 Láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ ni òkúta igun ilé ti jáde wá, láti ọ̀dọ̀ rẹ ni èèkàn àgọ́ tí wá, láti ọ̀dọ̀ rẹ ni ọrún ogun tí wá, láti ọ̀dọ̀ rẹ ni àwọn akóniṣiṣẹ́ gbogbo tí wá.
Köşe taşı, Çadır kazığı, Savaş yayı Ve bütün önderler Yahuda'dan çıkacak.
5 Gbogbo wọn yóò sì dàbí ọkùnrin alágbára ni ogun tí ń tẹ àwọn ọ̀tá wọn mọ́lẹ̀ ní ìgboro, wọn ó sì jagun, nítorí Olúwa wà pẹ̀lú wọn, wọn ó sì dààmú àwọn tí ń gun ẹṣin.
Savaşta düşmanlarını sokaklardaki çamurda çiğneyen yiğitler gibi olacaklar. RAB onlarla olduğu için Savaşacak ve atlıları utandıracaklar.
6 “Èmi o sì mú ilé Juda ní agbára, èmi o sì gba ilé Josẹfu là, èmi ó sì tún mú wọn padà nítorí mo tí ṣàánú fún wọn, ó sì dàbí ẹni pé èmi kò ì tì í ta wọ́n nù; nítorí èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn, èmi o sì gbọ́ tiwọn
“Yahuda halkını güçlendireceğim, Yusuf soyunu kurtarıp Sürgünden geri getireceğim. Çünkü onlara acıyorum. Sanki onları reddetmemişim gibi olacaklar. Çünkü ben onların Tanrısı RAB'bim ve onları yanıtlayacağım.
7 Efraimu yóò sì ṣe bí alágbára, ọkàn wọn yóò sì yọ̀ bi ẹni pé nípa ọtí wáìnì: àní àwọn ọmọ wọn yóò rí í, wọn o sì yọ̀, inú wọn ó sì dùn nínú Olúwa.
Efrayimliler yiğitler gibi olacaklar, Şarap içmiş gibi yürekleri coşacak. Çocukları bunu görüp neşelenecek, Yürekleri RAB'de sevinç bulacak.
8 Èmi ó kọ sí wọn, èmi ó sì ṣà wọ́n jọ; nítorí èmi tí rà wọ́n padà; wọn ó sì pọ̀ sí i gẹ́gẹ́ bí wọ́n tí ń pọ̀ sí í rí.
“Islık çalıp onları toplayacağım, Onları kesinlikle kurtaracağım. Eskiden olduğu gibi Yine çoğalacaklar.
9 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo tú wọn káàkiri orílẹ̀-èdè: síbẹ̀ wọn ó sì rántí mi ni ilẹ̀ jíjìn; wọn ó sì gbé pẹ̀lú àwọn ọmọ wọn, wọn ó sì tún padà.
Onları halklar arasına dağıttımsa da, Uzak ülkelerde beni anımsayacaklar; Çocuklarıyla birlikte sağ kalacak ve geri dönecekler.
10 Èmi ó sì tún mú wọn padà kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti pẹ̀lú, èmi ó sì ṣà wọn jọ kúrò ni ilẹ̀ Asiria. Èmi ó sì mú wọn wá sí ilẹ̀ Gileadi àti Lebanoni; a kì yóò sì rí ààyè fún wọn bí ó ti yẹ.
Onları Mısır'dan geri getirecek, Asur'dan toplayacağım; Gilat'a, Lübnan'a getireceğim. Onlara yeterince yer bulunmayacak.
11 Wọn yóò sì la Òkun wàhálà já, yóò sì bori rírú omi nínú Òkun, gbogbo ibú odò ni yóò sì gbẹ, a ó sì rẹ ìgbéraga Asiria sílẹ̀, ọ̀pá aládé Ejibiti yóò sí lọ kúrò.
Sıkıntı denizinden geçecekler, Denizin dalgaları yatışacak, Nil'in bütün derinlikleri kuruyacak. Asur'un gururu alaşağı edilecek, Mısır'ın krallık asası elinden alınacak.
12 Èmi ó sì mú wọn ní agbára nínú Olúwa; wọn ó sì rìn sókè rìn sódò ni orúkọ rẹ̀,” ni Olúwa wí.
Halkımı kendi gücümle güçlendireceğim, Adıma layık bir yaşam sürdürecekler.” Böyle diyor RAB.

< Zechariah 10 >