< Zechariah 10 >

1 Ẹ béèrè òjò nígbà àrọ̀kúrò ni ọwọ́ Olúwa; Olúwa tí o dá mọ̀nàmọ́ná, tí ó sì fi ọ̀pọ̀ òjò fún ènìyàn, fún olúkúlùkù koríko ní pápá.
Så beder nu af Herranom serlaregn, så skall Herren göra moln, och gifva eder regn nog till all växt på markene.
2 Nítorí àwọn òrìṣà tí sọ̀rọ̀ asán, àwọn aláfọ̀ṣẹ sì tí rí èké, wọn sì tí rọ àlá èké; wọ́n ń tu ni nínú lásán, nítorí náà àwọn ènìyàn náà ṣáko lọ bí àgùntàn, a ṣẹ wọn níṣẹ̀ẹ́, nítorí Olùṣọ́-àgùntàn kò sí.
Ty afgudarna tala icke annat än vedermödo, och spåmännerna se icke annat än lögn, och tala icke annat än fåfånga drömmar, och deras tröstning är intet; derföre gå de ville såsom får, och äro försmäktade, efter der är ingen herde.
3 “Ìbínú mi ru sí àwọn darandaran, èmi o sì jẹ àwọn olórí ní yà nítorí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti bẹ agbo rẹ̀, ilé Juda wò, yóò sì fi wọn ṣe ẹṣin rẹ̀ dáradára ní ogun.
Min vrede hafver förgrymmat sig öfver herdarna, och jag skall hemsöka bockarna; ty Herren Zebaoth skall söka sin hjord, nämliga Juda hus, och skall tillrusta dem, såsom en väl tillpyntad häst till strids.
4 Láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ ni òkúta igun ilé ti jáde wá, láti ọ̀dọ̀ rẹ ni èèkàn àgọ́ tí wá, láti ọ̀dọ̀ rẹ ni ọrún ogun tí wá, láti ọ̀dọ̀ rẹ ni àwọn akóniṣiṣẹ́ gbogbo tí wá.
Hörn, nagle, stridsbåge och drifvare, skola alle bort ifrå dem komma;
5 Gbogbo wọn yóò sì dàbí ọkùnrin alágbára ni ogun tí ń tẹ àwọn ọ̀tá wọn mọ́lẹ̀ ní ìgboro, wọn ó sì jagun, nítorí Olúwa wà pẹ̀lú wọn, wọn ó sì dààmú àwọn tí ń gun ẹṣin.
Och skola likväl ändå vara såsom hjeltar, de der träck trampa på gatomen i stridene, och skola strida; ty Herren skall vara med dem, att de resenärer skola till skam varda.
6 “Èmi o sì mú ilé Juda ní agbára, èmi o sì gba ilé Josẹfu là, èmi ó sì tún mú wọn padà nítorí mo tí ṣàánú fún wọn, ó sì dàbí ẹni pé èmi kò ì tì í ta wọ́n nù; nítorí èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn, èmi o sì gbọ́ tiwọn
Och jag skall stärka Juda hus, och hjelpa Josephs hus, och skall sätta dem åter in igen; ty jag förbarmar mig öfver dem, och de skola vara såsom de voro förra än jag fördref dem; ty jag, Herren deras Gud, vill höra dem.
7 Efraimu yóò sì ṣe bí alágbára, ọkàn wọn yóò sì yọ̀ bi ẹni pé nípa ọtí wáìnì: àní àwọn ọmọ wọn yóò rí í, wọn o sì yọ̀, inú wọn ó sì dùn nínú Olúwa.
Och Ephraim skall vara såsom en hjelte, och deras hjerta skall gladt varda, lika som af vin; dertill skola deras barn se det, och fröjda sig, och deras hjerta gladt vara i Herranom.
8 Èmi ó kọ sí wọn, èmi ó sì ṣà wọ́n jọ; nítorí èmi tí rà wọ́n padà; wọn ó sì pọ̀ sí i gẹ́gẹ́ bí wọ́n tí ń pọ̀ sí í rí.
Jag skall blåsa till dem, och församla dem; ty jag vill förlossa dem, och de skola förmera sig, såsom de sig tillförene förmerat hafva.
9 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo tú wọn káàkiri orílẹ̀-èdè: síbẹ̀ wọn ó sì rántí mi ni ilẹ̀ jíjìn; wọn ó sì gbé pẹ̀lú àwọn ọmọ wọn, wọn ó sì tún padà.
Och jag skall så dem ibland folk, att de skola tänka uppå mig i fjerran landom, och skola med sin barn lefva och igenkomma.
10 Èmi ó sì tún mú wọn padà kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti pẹ̀lú, èmi ó sì ṣà wọn jọ kúrò ni ilẹ̀ Asiria. Èmi ó sì mú wọn wá sí ilẹ̀ Gileadi àti Lebanoni; a kì yóò sì rí ààyè fún wọn bí ó ti yẹ.
Ty jag vill låta dem igenkomma utur Egypti land, och skall församla dem utur Assyrien, och låta dem komma uti Gileads land och Libanon, och dem skull intet fattas.
11 Wọn yóò sì la Òkun wàhálà já, yóò sì bori rírú omi nínú Òkun, gbogbo ibú odò ni yóò sì gbẹ, a ó sì rẹ ìgbéraga Asiria sílẹ̀, ọ̀pá aládé Ejibiti yóò sí lọ kúrò.
Och han skall gå igenom det trånga hafvet, och slå böljorna i hafvena, att alla djupa floder skola uttorkade varda. Så skall då förnedradt varda det prål i Assyrien, och spiran uti Egypten skall återvända.
12 Èmi ó sì mú wọn ní agbára nínú Olúwa; wọn ó sì rìn sókè rìn sódò ni orúkọ rẹ̀,” ni Olúwa wí.
Jag skall stärka dem i Herranom, så att de skola vandra uti hans Namn, säger Herren.

< Zechariah 10 >