< Song of Solomon 7 >

1 Báwo ni ẹsẹ̀ rẹ ti ní ẹwà tó nínú bàtà. Ìwọ ọmọbìnrin ọba! Oríkèé itan rẹ rí bí ohun ọ̀ṣọ́ iṣẹ́ ọlọ́gbọ́n oníṣọ̀nà
Wo nan ne mpaboa yɛ fɛ, Ao, ɔdehyeɛ babaa! Wʼanantuo a wogyina so te sɛ abohemaa, odwumfoɔ nsa ano adwuma.
2 Ìdodo rẹ rí bí àwo tí kì í ṣe aláìní ọtí, ìbàdí rẹ bí òkìtì alikama tí a fi lílì yíká.
Wo funuma yɛ kuruwa a ɛnni nsa a nsã pa wɔ mu ɛberɛ biara. Wo sisi yɛ atokoɔ a wɔaboa ano na sukooko atwa ho ahyia.
3 Ọmú rẹ rí bí abo egbin méjì tí wọ́n jẹ́ ìbejì àgbọ̀nrín.
Wo nufu te sɛ aforoteɛ mma mmienu, adabɔ mma ntafoɔ.
4 Ọrùn rẹ rí bí ilé ìṣọ́ eyín erin. Ojú rẹ rí bí adágún ní Heṣboni ní ẹ̀bá ẹnu ibodè Bati-Rabbimu. Imú rẹ rí bí ilé ìṣọ́ Lebanoni tí ó kọ ojú sí Damasku.
Wo kɔn te sɛ asonse abantenten. Wʼaniwa aba te sɛ Hesbon ntadeɛ a ɛwɔ Bat Rabim ɛpono nkyɛn. Wo hwene te sɛ Lebanon abantenten a ɛkyerɛ Damasko no.
5 Bí òkè Karmeli ṣe ṣe adé yí àwọn òkè ká, bẹ́ẹ̀ ni irun orí rẹ ṣe adé yí orí rẹ ká a fi àìdi irun rẹ mú ọba ní ìgbèkùn.
Wo tiri si so sɛ Karmel Bepɔ. Wo tirinwi te sɛ adehyetoma a wɔadi mu adwinneɛ; wo tirinwi tentene no dwomfa ɔhene.
6 Báwo ni ẹwà rẹ ti pọ̀ tó báwo ni o sì ti dára tó ìwọ olùfẹ́ mi nínú ìfẹ́?
Wo ho yɛ fɛ, Ao ɔdɔ, wo ho anikadeɛ ma wo ho yɛ ahomeka.
7 Ìdúró rẹ rí bí igi ọ̀pẹ, àti ọmú rẹ bí ìdì èso àjàrà.
Wo siberɛ te sɛ abɛ dua, na wo nufu te sɛ aduaba siaka.
8 Mo ní, “Èmi yóò gun igi ọ̀pẹ lọ, èmi yóò di ẹ̀ka rẹ̀ mú.” Kí ọmú rẹ rí bí ìdì èso àjàrà, àti èémí imú rẹ bí i ápù.
Mekaa sɛ, “Mɛforo abɛ dua no; na masɔ nʼaba mu.” Wo nufu nyɛ sɛ bobe siaka, na wo homeɛ mu hwa nyɛ sɛ aprɛ.
9 Àti ìfẹnukonu rẹ rí bí ọtí wáìnì tí ó dára jùlọ. Olólùfẹ́ Tí ó kúnná tí ó sì dùn, tí ń mú kí ètè àwọn tí ó sùn kí ó sọ̀rọ̀.
Na wʼanomu hwa nyɛ sɛ bobesa papa. Ababaawa: Ma bobesa no nkɔ me dɔfoɔ hɔ tee, ɛntene mfa nʼanofafa ne ne se no so brɛoo.
10 Ti olùfẹ́ mi ni èmi í ṣe, èmi sì ni ẹni tí ó wù ú.
Meyɛ me dɔfoɔ dea, na nʼapɛdeɛ ne me.
11 Wá, olùfẹ́ mi, jẹ́ kí a lọ sí ibi pápá, jẹ́ kí a lo àṣálẹ́ ní àwọn ìletò.
Bra, me dɔfoɔ; ma yɛnkɔ nkuraase, ma yɛnkɔda nkuraase anadwo baako.
12 Jẹ́ kí a lọ sínú ọgbà àjàrà ní kùtùkùtù láti wo bí àjàrà rúwé bí ìtànná àjàrà bá là. Àti bí pomegiranate bá ti rudi, níbẹ̀ ni èmi yóò ti fi ìfẹ́ mi fún ọ.
Ma yɛnkɔ bobefuo mu ntɛm nkɔhwɛ sɛ bobe no agu nhyerɛnne, sɛ nhyerɛnne no apaapae, anaasɛ ateaa no ayɛ frɔmm. Ɛhɔ na mede me dɔ bɛma wo.
13 Àwọn èso mándrákì mú òórùn wọn jáde ní ẹnu-ọ̀nà wa ni onírúurú àṣàyàn èso, èso tuntun àti ọjọ́ pípẹ́ tí mo ti kó pamọ́ fún ọ, olùfẹ́ mi.
Adasoa yi ne hwa, na akɔnnɔduane nyinaa bɛgu yɛn ɛpono ano, foforɔ ne dada, a mede asie ama woɔ, me dɔfoɔ.

< Song of Solomon 7 >