< Ruth 4 >
1 Nígbà náà ni Boasi gòkè lọ sí ẹnu ibodè ìlú, ó sì jókòó síbẹ̀. Nígbà tí ìbátan tí ó súnmọ́ Elimeleki jùlọ, arákùnrin tí Boasi ti sọ̀rọ̀ rẹ̀ ń kọjá, Boasi pè é wí pé, “Máa bọ̀ wá síbí ìwọ ọ̀rẹ́ mi, kí o sì jókòó.” Ó sì lọ jókòó.
Боаз с-а суит ла поарта четэций ши с-а оприт аколо. Ши ятэ кэ чел че авя дрепт де рэскумпэраре, ши деспре каре ворбисе Боаз, тречя. Боаз й-а зис: „Хей, кутаре, апропие-те, стай аич.” Ши ел с-а апропият ши с-а оприт.
2 Boasi sì pe mẹ́wàá nínú àwọn àgbàgbà ìlú, wí pé ki wọn jókòó, wọn sí ṣe bẹ́ẹ̀,
Боаз а луат атунч зече оамень динтре бэтрыний четэций ши а зис: „Шедець аич.” Ши ей ау шезут жос.
3 ó sì sọ fún ìbátan rẹ̀ náà pé, “Arábìnrin Naomi tí ó dé láti ilẹ̀ Moabu fẹ́ ta ilẹ̀, èyí tí ó ṣe ti arákùnrin Elimeleki wa.
Апой а зис челуй че авя дрепт де рэскумпэраре: „Наоми, ынторкынду-се дин цара Моабулуй, а вындут буката де пэмынт каре ера а фрателуй ностру Елимелек.
4 Mó sì rò wí pé ó yẹ kí n mú ọ̀rọ̀ náà wá sí etí ìgbọ́ rẹ, wí pé kí o rà á ní iwájú gbogbo àwọn tí ó jókòó sí ibi yìí. Bí ìwọ yóò bá rà á padà rà á. Ṣùgbọ́n bí ìwọ kò bá ní rà á padà, sọ fún mi, kí èmi ó le è mọ̀. Nítorí pé kò sí ẹlòmíràn tí ó ní ẹ̀tọ́ láti rà á ju ìwọ lọ, èmi sì ni ẹni tí ó tún kàn lẹ́yìn rẹ̀.” Ọkùnrin náà sì sọ wí pé, “Èmi yóò rà á padà.”
Ам крезут де датория мя сэ те ынштиинцез деспре ачаста ши сэ-ць спун: ‘Кумпэр-о ын фаца локуиторилор ши ын фаца бэтрынилор попорулуй меу. Дакэ врей с-о рэскумперь, рэскумпэр-о; дар дакэ ну врей, спуне-мь, ка сэ штиу. Кэч ну есте нимень ынаинтя та каре сэ айбэ дрептул де рэскумпэраре, ши дупэ тине еу ам дрептул ачеста.’” Ши ел а рэспунс: „О вой рэскумпэра.”
5 Nígbà náà ni Boasi sọ wí pé, “Bí ìwọ bá ti ra ilẹ̀ náà lọ́wọ́ Naomi àti lọ́wọ́ Rutu ará Moabu, ìwọ gbọdọ̀ fẹ́ opó ọkùnrin náà, kí orúkọ ọkùnrin tí ó kú náà má ba à parẹ́ pẹ̀lú ohun ìní rẹ̀ àti kí o le è bímọ ní orúkọ rẹ̀.”
Боаз а зис: „Ын зиуа ын каре вей кумпэра царина дин мына Наомей, о вей кумпэра ын ачелашь тимп ши де ла Рут, Моабита, неваста челуй морт, ка сэ ридичь нумеле мортулуй ын моштениря луй.”
6 Nígbà náà ni ọkùnrin náà dáhùn sí èyí pé, “Nípa ti èyí, èmi kò le è rà á padà, nítorí pé, ọmọ rẹ̀, ọkùnrin yóò wá jẹ́ ajogún àwọn ohun ìní mi pẹ̀lú. Rà á fún ara rẹ, èmi kò le ṣe é.”
Ши чел че авя дрепт де рэскумпэраре а рэспунс: „Ну пот с-о рэскумпэр пе сокотяла мя, де фрикэ сэ ну-мь стрик моштениря мя; я ту дрептул де рэскумпэраре, кэч еу ну пот с-о рэскумпэр.”
7 Ní ayé ìgbàanì, kí a tó le sọ wí pé ohun ìràpadà tàbí pàṣípàrọ̀ ohun ìní fi ìdí múlẹ̀ ní ilẹ̀ Israẹli, ẹnìkan ni láti yọ bàtà rẹ̀ kúrò ní ẹsẹ̀ rẹ̀ kí ó sì fi fún ẹnìkejì, ó jẹ́ òfin fún ẹni tí ó fẹ́ rà á. Nípa ṣíṣe èyí, àwọn ará Israẹli fihàn wí pé ọ̀rọ̀ náà ti fìdímúlẹ̀.
Одиниоарэ ын Исраел, пентру ынтэриря уней рэскумпэрэрь сау а унуй скимб, омул ышь скотя ынкэлцэминтя ши о дэдя челуйлалт: ачаста служя ка мэртурие ын Исраел.
8 Nítorí náà, nígbà tí ọkùnrin náà sọ fún Boasi wí pé, “Ìwọ rà á fúnra rẹ̀,” ó yọ bàtà rẹ̀ kúrò ní ẹsẹ̀ rẹ̀.
Чел че авя дрепт де рэскумпэраре а зис дар луй Боаз: „Кумпэр-о пе сокотяла та!” Ши шь-а скос ынкэлцэминтя.
9 Nígbà náà ni Boasi wí fún àwọn àgbàgbà àti àwọn mìíràn tí ó wà ní ibẹ̀ pé, “Gbogbo yín jẹ́ ẹlẹ́rìí mi ní òní wí pé mo ti ra ohun gbogbo tí í ṣe ti Elimeleki àti àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin méjèèjì: Maloni àti Kilioni lọ́wọ́ Naomi.
Атунч, Боаз а зис бэтрынилор ши ынтрегулуй попор: „Вой сунтець марторь азь кэ ам кумпэрат дин мына Наомей тот че ера ал луй Елимелек, ал луй Килион ши ал луй Махлон
10 Ní àfikún, mo ra Rutu ará Moabu opó Maloni padà láti di aya mi. Èyí tí yóò mú kí orúkọ ọkùnrin òkú náà wà pẹ̀lú ohun ìní rẹ̀, kí ìran rẹ̀ má ba à lè parẹ́ láàrín àwọn ẹbí rẹ̀ àti ìlú rẹ̀. Ẹ̀yin ni ẹlẹ́rìí ní òní.”
ши кэ мь-ам кумпэрат, де асеменя, де невастэ пе Рут, Моабита, неваста луй Махлон, ка сэ ридик нумеле мортулуй ын моштениря луй ши пентру ка нумеле мортулуй сэ ну фие штерс динтре фраций луй ши дин поарта локулуй луй. Вой сунтець марторь азь деспре ачаста!”
11 Nígbà náà ni àwọn àgbàgbà àti àwọn ènìyàn tí ó wà ní ibẹ̀ dáhùn wí pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, àwa ni ẹlẹ́rìí, kí Olúwa jẹ́ kí obìnrin tí ó ń bọ̀ wá sí inú ilẹ̀ rẹ dàbí Rakeli àti Lea láti ara àwọn ẹni tí gbogbo ìdílé Israẹli ti jáde wá. Kí ìwọ sì di ọlọ́rọ̀ ní ìran Efrata àti olókìkí ní ìlú Bẹtilẹhẹmu.
Тот попорул каре ера ла поартэ ши бэтрыний ау зис: „Сунтем марторь! Домнул сэ факэ пе фемея каре интрэ ын каса та ка Рахела ши ка Лея, каре амындоуэ ау зидит каса луй Исраел! Аратэ-ць путеря ын Ефрата ши фэ-ць ун нуме ын Бетлеем!
12 Kí Olúwa fún ọ ní ọmọ tí yóò mú ìdílé rẹ dàbí ti Peresi ọmọkùnrin tí Tamari bí fún Juda láti ipasẹ̀ ọ̀dọ́mọbìnrin yìí.”
Сэмынца пе каре ць-о ва да Домнул прин ачастэ тынэрэ фемее сэ-ць факэ о касэ асеменя касей луй Перец, каре с-а нэскут луй Иуда дин Тамар!”
13 Báyìí ni Boasi ṣe mú Rutu, tí ó sì di aya rẹ̀. Nígbà náà ni ó wọlé tọ aya rẹ̀, Olúwa sì mú kí ó lóyún, ó sì bí ọmọ ọkùnrin kan.
Боаз а луат пе Рут, каре й-а фост невастэ, ши ел а интрат ла еа. Домнул а фэкут-о сэ зэмисляскэ ши еа а нэскут ун фиу.
14 Àwọn obìnrin sì wí fún Naomi pé, “Ìyìn ni fún Olúwa tí kò fi ọ sílẹ̀ ní òní yìí láìní ìbátan, Olùràpadà. Kí ọmọ náà di olókìkí ní Israẹli.
Фемеиле ау зис Наомей: „Бинекувынтат сэ фие Домнул, каре ну те-а лэсат липситэ азь де ун бэрбат ку дрепт де рэскумпэраре ши ал кэруй нуме ва фи лэудат ын Исраел!
15 Yóò tún ayé rẹ ṣe, yóò sì dáàbò bò ọ́ ní ọjọ́ ogbó rẹ. Nítorí pé ìyàwó ọmọ rẹ, èyí tí ó sàn fún ọ ju ọmọkùnrin méje lọ, tí ó sì fẹ́ràn rẹ ni ó bí ọmọ yìí fún.”
Копилул ачеста ыць ва ынвиора суфлетул ши ва фи сприжинул бэтрынецилор тале, кэч л-а нэскут норэ-та, каре те юбеште ши каре фаче пентру тине май мулт декыт шапте фий.”
16 Naomi sì gbé ọmọ náà lé orí ẹsẹ̀ rẹ̀, ó sì ń tọ́jú rẹ̀.
Наоми а луат копилул, л-а цинут ын браце ши а вэзут де ел.
17 Àwọn obìnrin àdúgbò sì wí pé, “A bí ọmọkùnrin kan fún Naomi.” Wọ́n sì pe orúkọ rẹ̀ ní Obedi. Òun sì ni baba Jese tí í ṣe baba Dafidi.
Вечинеле й-ау пус нуме, зикынд: „Ун фиу с-а нэскут Наомей!” Ши л-ау нумит Обед. Ачеста а фост татэл луй Исай, татэл луй Давид.
18 Èyí ni ìran Peresi: Peresi ni baba Hesroni,
Ятэ сэмынца луй Перец. Перец а фост татэл луй Хецрон;
19 Hesroni ni baba Ramu, Ramu ni baba Amminadabu
Хецрон а фост татэл луй Рам; Рам а фост татэл луй Аминадаб;
20 Amminadabu ni baba Nahiṣoni, Nahiṣoni ni baba Salmoni,
Аминадаб а фост татэл луй Нахшон; Нахшон а фост татэл луй Салмон;
21 Salmoni ni baba Boasi, Boasi ni baba Obedi,
Салмон а фост татэл луй Боаз; Боаз а фост татэл луй Обед;
22 Obedi ní baba Jese, Jese ni baba Dafidi.
Обед а фост татэл луй Исай ши Исай а фост татэл луй Давид.