< Ruth 3 >

1 Ní ọjọ́ kan, Naomi, ìyá ọkọ Rutu wí fún un pé, “Ọmọbìnrin mi, ǹjẹ́ kò yẹ kí èmi bá ọ wá ilé ọkọ mìíràn, níbi tí wọn yóò ti le è máa tọ́jú rẹ?
A LAILA, olelo mai o Naomi kona makuahonowaiwahine, E kuu kaikamahine, aole anei au e imi i wahi e hoomaha ai nou, i mea e pomaikai ai oe?
2 Wò ó, Boasi ọkùnrin nì tí ìwọ bá àwọn ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀ ṣiṣẹ́, tí í ṣe ìbátan wa, yóò wá láti fẹ́ ọkà barle ní ilẹ̀ ìpakà rẹ̀ ní àṣálẹ́ yìí.
Aole anei no ko kakou hoahanau o Boaza, nona na kaikamahine au i noho pu ai? Aia hoi ke kanana nei ia i ka huabale i keia po ma ke kahua hahi.
3 Wẹ̀, kí o sì fi ìpara olóòórùn dídùn pa ara rẹ, kí o sì wọ aṣọ rẹ tí ó dára jùlọ, kí o sì lọ sí ilẹ̀ ìpakà tí ó gbé ń pa ọkà, ṣùgbọ́n má ṣe jẹ́ kí ó mọ̀ pé o wà níbẹ̀ títí tí yóò fi jẹ tí yóò sì mu tán.
Nolaila ea, e holoi oe ia oe iho, a e hamo hoi, a e hookomo i kou lole, a e iho oe ilalo i ke kahua; a mai hoike aku oe ia oe iho i ua kanaka la, a pau kana ai ana, a me kana inu ana.
4 Rí í dájú pé o mọ ibi tí ó sùn sí, lẹ́yìn ìgbà tí ó bá ti sùn, lọ kí o ṣí aṣọ ìbora rẹ̀ níbi ẹsẹ̀ rẹ̀ sókè kí o sì sùn sí ibi ẹsẹ̀ náà. Òun yóò sì sọ ohun tí ìwọ yóò ṣe fún ọ.”
Eia hoi kekahi; i ka manawa ana e moe ai, e nana pono oe i kona wahi e moe ana, a e komo aku oe, a e wehe i kona mau kapuwai, a moe iho, a nana no e hai mai ia oe i ka mea au e hana'i.
5 Rutu sì fèsì pé, “Gbogbo ohun tí ìwọ sọ fún mi ni èmi yóò ṣe.”
I aku la keia ia ia, O na mea a pau au e kauoha mai nei, e hana no au.
6 Bẹ́ẹ̀ ni Rutu lọ sí ilẹ̀ ìpakà tí ó sì ṣe gbogbo ohun tí ìyá ọkọ rẹ̀ sọ fún un, pé kí o ṣe.
Iho aku la oia ilalo i ke kahua, a hana iho la e like me na mea a pau a kona makuahonowaiwahine i kauoha mai ai ia ia.
7 Nígbà tí Boasi parí jíjẹ àti mímu tán, tí ọkàn rẹ̀ sì kún fún ayọ̀. Ó lọ, ó sì dùbúlẹ̀ ní ẹ̀yìn ọkà tí wọ́n kójọ. Rutu yọ́ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ lọ sí ibẹ̀, ó ṣí aṣọ ẹsẹ̀ rẹ̀ sókè, ó sì sùn sí ibi ẹsẹ̀ rẹ̀.
A ai o Boaza, a inu, a olioli kona naau, alaila, hele aku la ia e moe ma ka welau a ka puu ai; a hele malie mai la ia, a wehe iho la i kona mau kapuwai, a moe iho la.
8 Ó sì ṣe nígbà tí ọkùnrin náà tají ní àárín òru, ẹ̀rù bà á, ó sì yí ara padà, ó sì ṣàkíyèsí obìnrin kan tí ó sùn sí ibi ẹsẹ̀ rẹ̀.
A hiki i ke aumoe, makau iho la ua kanaka la, no ka mea, i kona oni ana, aia hoi he wahine, e moe ana ma kona mau kapuwai.
9 Ó sì béèrè pé, “Ta ni ìwọ í ṣe?” Rutu sì fèsì wí pé, “Èmi ni Rutu, ìránṣẹ́bìnrin rẹ. Da etí aṣọ rẹ bò mí, nítorí pé ìwọ ni ìbátan tí ó le è rà mí padà.”
I mai la ia, Owai oe? I mai la kela, o Ruta wau, o kau kauwawahine, nolaila ea, e halii mai i kou kapa maluna o kau kauwawahine, no ka mea, o oe no kekahi mea i pili koko.
10 Boasi sì wí fún un pé, “Kí Olúwa bùkún fún ọ, ọmọbìnrin mi. Ìfẹ́ tí o fihàn yí ti pọ̀ ju ti àtẹ̀yìnwá lọ, bí ó ti jẹ́ wí pé ìwọ kò lọ láti wá àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin bóyá ọlọ́rọ̀ tàbí tálákà.
I mai la ia, E pomaikai ana oe ia Iehova, e kuu kaikamahine e; no ka mea, ua oi aku kou lokomaikai hope, i ko ka mua, i kou hahai ole ana mahope o na kanaka ui, aole i ka mea hune, aole hoi i ka mea waiwai.
11 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ìwọ ọmọbìnrin mi, má bẹ̀rù. Èmi yóò sì ṣe ohun gbogbo tí o béèrè fún ọ. Gbogbo ènìyàn ni ó mọ̀ ọ́n ní obìnrin oníwà rere.
Nolaila ea, mai makau oe, e kuu kaikamahine. O na mea a pau au e olelo mai la, na'u ia e hana aku ia oe; no ka mea, ua ike ko'u poe kanaka a pau, he kaikamahine pono oe.
12 Nítòótọ́ ni mo wí pé èmi jẹ́ ìbátan tí ó súnmọ́ ọ, ṣùgbọ́n ìbátan kan wà tí ó súnmọ́ ọ ju ti tèmi lọ.
He oiaio no, owau ka hoahanau pili ia oe. Eia ae kekahi mea i pili mua aku, he hope au.
13 Dúró síbí títí ilẹ̀ yóò fi mọ́, bí ó bá sì di òwúrọ̀ tí ọkùnrin náà sì ṣe tan láti ṣe ìràpadà, ó dára kí ó ṣe bẹ́ẹ̀, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, bí Olúwa ti ń bẹ láààyè nígbà náà ni èmi yóò ṣe ìràpadà, sùn sí ìhín títí ilẹ̀ yóò fi mọ́.”
I keia po e kakali ai a kakahiaka, alaila, ina nana oe e mare, ua pono, e mare no ia; aka, ina aole ia e makemake e mare mai ia oe, ma ke ola ana o Iehova, na'u oe e mare. E moe oe a kakahiaka.
14 Ó sì sùn ní ẹsẹ̀ rẹ̀ títí di òwúrọ̀, ṣùgbọ́n ó dìde ní òwúrọ̀ kùtùkùtù kí ẹnìkínní tó le è dá ẹnìkejì mọ̀. Boasi sì sọ fún un wí pé, “Má ṣe jẹ́ kí ó di mí mọ̀ wí pé obìnrin kan wá sí ilẹ̀ ìpakà.”
Moe iho la oia ma kona mau kapuwai a kakahiaka. A ala mai la ia mamua o ka wa e hiki ai kekahi ke hoomaopopo i kona hoa. I ae la ia, Mai hai aku i ka hele ana mai o ka wahine i ke kahua hahi.
15 Ó sì tún wí fún un pé, “Mú aṣọ ìborùn rẹ tí o dà bora, kí o tẹ̀ ẹ sílẹ̀.” Rutu sì ṣe bẹ́ẹ̀, Boasi sì wọn òsùwọ̀n ọkà barle mẹ́fà sí i, ó sì gbé e rù ú. Nígbà náà ni ó padà sí ìlú.
I hou aku la ia, Homai ka pale maluna ou, a e paa mai ia mea. A i kona paa ana mai, ana iho la ia i eono ana huabale, a kau aku la maluna ona; a hoi aku la ia i ke kulanakauhale.
16 Nígbà tí Rutu dé ilé Naomi ìyá ọkọ sì bí léèrè pé, “Báwo ni ó ti rí ọmọbìnrin mi?” Nígbà náà ni ó sì sọ gbogbo ohun tí ọkùnrin náà ṣe fún un fún ìyá ọkọ rẹ̀.
A hiki aku la ia i kona makuahonowaiwahine, ninau mai la kela, Owai oe, e kuu kaikamahine? A hai aku la keia i na mea a pau a ua kanaka la i hana mai ai nana.
17 Ó fi kún un wí pé, “Ó sọ fún mi wí pé, ‘Má ṣe padà sí ọ̀dọ̀ ìyá ọkọ rẹ ní ọwọ́ òfo, nítorí náà, ó fún mi ní ìwọ̀n ọkà barle mẹ́fà.’”
I aku la, O keia mau ana huabale eono kana i haawi mai ai ia'u; no ka mea, olelo mai la ia, Mai hoi nele aku oe i kou makuahonowaiwahine.
18 Naomi sì wí fún un pé, “Dúró, ọmọbìnrin mi títí tí ìwọ yóò fi mọ bí ohun gbogbo yóò ti rí, nítorí pé ọkùnrin náà kò ní sinmi títí tí ọ̀rọ̀ náà yóò fi yanjú lónìí.”
Olelo mai la ia, E noho malie oe, e kuu kaikamahine, a ike pono oe i ka hope o keia; no ka mea, aole loa e noho hoomaha kela kanaka, a hoopau pono oia ia mea, i keia la.

< Ruth 3 >