< Ruth 2 >
1 Naomi ní ìbátan kan láti ìdílé Elimeleki ọkọ rẹ̀, aláàánú ọlọ́rọ̀, ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Boasi.
Na rĩrĩ, Naomi nĩarĩ na mũndũ wa mbarĩ yao mwena wa mũthuuriwe, kuuma mũhĩrĩga wa Elimeleku, mũndũ warĩ igweta, wetagwo Boazu.
2 Rutu ará Moabu sì wí fún Naomi pé, “Jẹ́ kí èmi kí ó lọ sí inú oko láti ṣá ọkà tí àwọn olùkórè fi sílẹ̀ ní ọ̀dọ̀ ẹnikẹ́ni tí èmi yóò bá ojúrere rẹ̀ pàdé.” Naomi sì sọ fún un pé, “Máa lọ, ọmọbìnrin mi.”
Nake Ruthu ũcio Mũmoabi akĩĩra Naomi atĩrĩ, “Reke thiĩ mĩgũnda-inĩ ngahaare cairi ĩrĩa ĩtigĩtio; ndĩ thuutha wa mũndũ o wothe ũrĩa ingĩĩtĩkĩrĩka maitho-inĩ make.” Nake Naomi akĩmwĩra atĩrĩ, “Thiĩ, mwarĩ wakwa.”
3 Rutu sì jáde lọ láti ṣá ọkà tí àwọn olùkórè fi sílẹ̀ lẹ́yìn wọn. Ó wá jẹ́ wí pé inú oko Boasi tí ó ti ìdílé Elimeleki wá ni ó lọ láìmọ̀-ọ́n-mọ̀.
Nĩ ũndũ ũcio akiumagara agĩthiĩ, akĩambĩrĩria kũhaara cairi kũu mĩgũnda-inĩ arĩ thuutha wa arĩa maagethaga. Na gũgĩkinya atĩrĩ, Ruthu ekorire akĩruta wĩra mũgũnda wa Boazu, ũcio warĩ wa mũhĩrĩga wa Elimeleku.
4 Nígbà náà ni Boasi dé láti Bẹtilẹhẹmu tí ó sì kí àwọn olùkórè wí pé, “Kí Olúwa wà pẹ̀lú yín.” Wọ́n sì dá a lóhùn pé, “Kí Olúwa bùkún fún ọ.”
O hĩndĩ ĩyo Boazu agĩkinya oimĩte Bethilehemu, na akĩgeithia acio maagethaga, akĩmeera atĩrĩ, “Jehova aroikara na inyuĩ!” Nao makĩmũcookeria atĩrĩ, “Jehova arokũrathima!”
5 Boasi sì béèrè lọ́wọ́ olórí àwọn olùkórè wí pé, “Ti ta ni ọ̀dọ́mọbìnrin yẹn?”
Boazu akĩũria mũrũgamĩrĩri wa acio maagethaga atĩrĩ, “Mũirĩtu ũũrĩa nĩ wa ũ?”
6 Ìránṣẹ́ tí ó jẹ́ olórí àwọn olùkórè náà sì fèsì pé, “Ọ̀dọ́mọbìnrin ará Moabu tí ó tẹ̀lé Naomi wá láti ilẹ̀ Moabu ni.
Nake mũrũgamĩrĩri akĩmũcookeria atĩrĩ, “Nĩ Mũmoabi ũrĩa wokire na Naomi kuuma bũrũri wa Moabi.
7 Ó sọ wí pé, ‘Kí ń jọ̀wọ́ jẹ́ kí òun máa ṣá ọkà lẹ́yìn àwọn olùkórè.’ Ó sì ti ń ṣe iṣẹ́ kárakára láti òwúrọ̀ títí di ìsinsin yìí nínú oko àyàfi ìgbà tí ó lọ láti sinmi fún ìgbà díẹ̀ lábẹ́ ibojì.”
Nake oigire atĩrĩ, ‘Ndagũthaitha ũnjĩtĩkĩrie haare cairi, na nyũnganie ĩrĩa ĩtigĩtio itĩĩa-inĩ ndĩ thuutha wa agethi.’ Nake aathiĩ mũgũnda, na arutĩte wĩra ategũtigithĩria kuuma o rũciinĩ nginya rĩu, tiga o ihinda inini ekũhurũkĩte haarĩa kĩĩruru-inĩ.”
8 Nígbà náà ni Boasi sọ fún Rutu pé, “Gbọ́ ọmọbìnrin mi, má ṣe lọ sí oko mìíràn láti ṣá ọkà, má sì ṣe kúrò ní ibi. Dúró níbí pẹ̀lú àwọn ìránṣẹ́bìnrin mi.
Nĩ ũndũ ũcio Boazu akĩĩra Ruthu atĩrĩ, “Mwarĩ wakwa, ta thikĩrĩria, ndũgathiĩ kũhaara cairi mũgũnda ũngĩ, na ndũkae kuuma gũkũ. Ikara gũkũ mũrĩ na ndungata ciakwa cia airĩtu.
9 Wo ibi tí wọ́n ti ń kórè kí o sì máa tẹ̀lé àwọn obìnrin. Mo ti pàṣẹ fún àwọn ọkùnrin kí wọ́n má ṣe fi ọwọ́ kàn ọ́. Nígbàkígbà tí òǹgbẹ bá sì ń gbẹ ọ́, lọ kí ó sì mu omi nínú àmù èyí tí àwọn ọkùnrin ti pọn omi sí nínú.”
Ũrorage mũgũnda ũrĩa arũme aya megũkorwo makĩgetha, na ũtwaranage na airĩtu acio. Nĩndakaania arũme aya matigakũhutie. Na rĩrĩa rĩothe ũngĩnyoota, ũthiĩ ũnyue maaĩ kuuma ndigithũ-inĩ iria arũme aya matahĩrĩire.”
10 Rutu wólẹ̀, ó sì wí fún Boasi pé, “Èéṣe tí èmi fi bá ojúrere rẹ pàdé tó báyìí, tí o sì kíyèsi mi, èmi àjèjì àti àlejò?”
Rĩrĩa Ruthu aiguire ũguo, akĩinamĩrĩra, agĩturumithia ũthiũ thĩ. Akiuga atĩrĩ, “Nĩ kĩĩ gĩatũma njĩtĩkĩrĩke maitho-inĩ maku na wenda kũnjĩka maũndũ mega, ndĩ o mũndũ wa kũngĩ?”
11 Boasi sì fèsì wí pé, “Èmi ti gbọ́ gbogbo bí o ti ń ṣe sí ìyá ọkọ ọ̀ rẹ láti ìgbà tí ọkọ rẹ ti kú àti bí o ti ṣe fi baba àti ìyá rẹ àti ilẹ̀ rẹ sílẹ̀, tí o sì wá láti gbé láàrín àwọn ènìyàn tí ìwọ kò mọ̀ tẹ́lẹ̀ rí.
Boazu akĩmũcookeria atĩrĩ, “Nĩnjĩĩrĩtwo maũndũ marĩa mothe wĩkĩte nyaciaraguo kuuma hĩndĩ ĩrĩa mũthuuriguo aakuire, na ũrĩa watiganire na thoguo na nyũkwa, o na bũrũri wanyu, ũgĩũka kũrĩ andũ ũtaamenyanĩte nao mbere ĩyo.
12 Kí Olúwa kí ó san ẹ̀san ohun tí ìwọ ṣe fún ọ. Kí o sì gba èrè kíkún láti ọ̀dọ̀ Olúwa Ọlọ́run Israẹli, abẹ́ ìyẹ́ ẹni tí ìwọ sá wá fún ààbò.”
Jehova arokũrĩha nĩ ũndũ wa ũguo wĩkĩte. Jehova Ngai wa Isiraeli, o ũrĩa wee ũũkĩte kwĩhitha mathagu-inĩ make, arokũrĩha na irĩhi inene.”
13 Rutu sì fèsì wí pé, “Kí èmi kí ó máa rí ojúrere láti ọ̀dọ̀ rẹ síwájú sí i olúwa mi. Ìwọ ti tù mí nínú nípa sísọ ọ̀rọ̀ rere sí ìránṣẹ́bìnrin rẹ, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé èmi kò tó ọ̀kan nínú àwọn ìránṣẹ́bìnrin rẹ.”
Nake Ruthu akiuga atĩrĩ, “Mwathi wakwa, ndĩrookĩrĩrĩria gwĩtĩkĩrĩka maitho-inĩ maku. Nĩũũhooreretie, na ũkaarĩria ndungata yaku ndeto njega cia tha, o na gũtuĩka niĩ ndirĩ ta ũmwe wa ndungata ciaku cia airĩtu.”
14 Nígbà tí àkókò oúnjẹ sì tó, Boasi sọ fún Rutu pé, “Wá gba ìwọ̀n àkàrà yìí kí o sì fi run wáìnì kíkan.” Òun sì jókòó pẹ̀lú àwọn olùkórè, Boasi sì fún un ní ọkà yíyan. Òun sì jẹ́, ó yó, ó sì tún ṣẹ́kù.
Hĩndĩ ya kũrĩa irio yakinya, Boazu akĩmwĩra atĩrĩ, “Ũka haha. Oya mũgate ũũtobokie thiki-inĩ ya ndibei.” Rĩrĩa Ruthu aikarire thĩ na agethi, Boazu akĩmũhe cairi hĩhie. Nake akĩrĩa akĩhũũna, o nginya agĩtigia.
15 Nígbà tí ó sì dìde láti máa ṣá ọkà, Boasi pàṣẹ fún àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ wí pé, “Bí ó tilẹ̀ ń ṣà láàrín oko ọkà pàápàá, ẹ má ṣe dí i lọ́wọ́.
Na hĩndĩ ĩrĩa ookĩrire akahaare-rĩ, Boazu agĩatha andũ ake akĩmeera atĩrĩ, “O na ahaara kũu itĩĩa-inĩ, mũtikamũtetie.
16 Bí kò ṣe pé kí ẹ mú lára àwọn ìtí sílẹ̀ fún láti ṣá, kí ẹ má sì ṣe ba a wí.”
O na nĩ kaba mũrutage cairi ĩmwe kuuma itĩĩa-inĩ, mũmĩrekie thĩ nĩ ũndũ wake, mũmũtigĩre nĩguo oke akĩmĩhaaraga, no mũtikamũtetie.”
17 Rutu sì ń ṣá ọkà títí ó fi di ìrọ̀lẹ́, nígbà tí ó sì pa ọkà barle tí ó rí ṣà, tí ó sì fẹ́ ẹ tán, èyí tí ó rí sì tó ìwọ̀n garawa kan (lita méjìlélógún).
Nĩ ũndũ ũcio Ruthu akĩhaara kũu mũgũnda ũcio nginya o hwaĩ-inĩ. Agĩcooka akĩhũũra cairi ĩrĩa aahaarĩte, ĩgĩkinyia mũigana wa eba ĩmwe.
18 Ó sì gbé e, ó sì lọ sí ìlú, ìyá ọkọ rẹ sì rí ọkà tí ó rí ṣà bi o tí pọ̀ tó, Rutu sì mú oúnjẹ tí ó jẹ kù lẹ́yìn tí ó ti yó tan fún ìyá ọkọ rẹ̀.
Akĩmĩkuua, agĩcooka itũũra-inĩ, nake nyaciarawe akĩona cairi ĩrĩa yothe aahaarĩte. Ruthu agĩcooka akĩmũrutĩra kĩrĩa aatigĩtie aahũũna, akĩmũnengera.
19 Ìyá ọkọ rẹ̀ sì bi í léèrè wí pé, “Níbo ni ìwọ ti ṣá ọkà lónìí? Àti wí pé oko ta ni ìwọ gbé ṣiṣẹ́? Alábùkún fún ni ọkùnrin náà tí ó bojú wò ọ.” Rutu sì sọ ọ̀dọ̀ ẹni tí ó ti ṣiṣẹ́ fún ìyá ọkọ rẹ̀ pé, “Ní oko ọkùnrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Boasi ni mo ti ṣiṣẹ́ lónìí.”
Nyaciarawe akĩmũũria atĩrĩ, “Ũmũthĩ uuma kũhaara kũ? Uuma kũruta wĩra kũ? Kũrathimwo nĩ mũndũ ũcio ũkũmenyire, agwĩka maũndũ mega!” Nake Ruthu akĩhe nyaciarawe ũhoro ũkoniĩ mwene mũgũnda ũcio aatindĩte akĩruta wĩra, akiuga atĩrĩ, “Mwene mũgũnda ũcio ngũrutaga wĩra gwake ũmũthĩ-rĩ, etagwo Boazu.”
20 Naomi sì wí fún un pé, “Kí Olúwa, kí ó bùkún fún ọkùnrin náà. Ọlọ́run kò dáwọ́ oore àti àánú ṣíṣe sí àwọn alààyè àti òkú dúró.” Naomi sì sọ síwájú sí i wí pé, “Ìbátan tí ó súnmọ́ wa pẹ́kípẹ́kí ni ọkùnrin náà ń ṣe, ó sì jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn tí ó ní ẹ̀tọ́ láti ra ohun ìní ìdílé padà.”
Naomi akĩĩra mũtumia ũcio wa mũriũ atĩrĩ, “Jehova aromũrathima! We ndatigĩte gwĩka maũndũ ma ũtugi kũrĩ arĩa me muoyo, o na arĩa makuĩte.” Ningĩ Naomi akĩĩra Ruthu atĩrĩ, “Mũndũ ũcio nĩ wa mbarĩ iitũ; o na nĩ ũmwe wa arĩa mangĩtũmenyerera.”
21 Rutu, ará Moabu sì wí pé, “Ju gbogbo rẹ̀ lọ, ó sọ fún mi pé, ‘Kí ń máa ṣá ọkà pẹ̀lú àwọn òṣìṣẹ́ òun, títí wọn yóò fi parí ìkórè.’”
Nake Ruthu ũcio Mũmoabi akiuga atĩrĩ, “O na anjĩĩrire atĩrĩ, ‘Ikara na aruti akwa a wĩra o nginya marĩkie kũgetha cairi yakwa yothe.’”
22 Naomi sì sọ fún Rutu, ìyàwó ọmọ rẹ̀ pé, “Ìbá dára bí ó bá le bá àwọn ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀ ṣiṣẹ́. Nítorí pé wọ́n le è dà ọ́ láàmú bí o bá lọ sí oko ẹlòmíràn.”
Naomi akĩĩra Ruthu ũcio mũtumia wa mũriũ atĩrĩ, “Ũndũ ũcio wa gũtwarana na airĩtu ake nĩũgũtuĩka mwega harĩwe, wee mwarĩ wakwa, tondũ mũgũnda-inĩ wa mũndũ ũngĩ wahota kũgerwo ngero.”
23 Rutu sì bá àwọn ìránṣẹ́bìnrin Boasi ṣiṣẹ́ títí tí wọ́n fi parí ìkórè ọkà barle àti ti jéró. Ó sì ń gbé pẹ̀lú ìyá ọkọ rẹ̀.
Nĩ ũndũ ũcio Ruthu agĩikara hakuhĩ na ndungata cia airĩtu cia Boazu akĩhaaraga nginya magetha ma cairi na ma ngano magĩthira. Nake agĩtũũra na nyaciarawe.