< Romans 9 >

1 Òtítọ́ ni èmi ń sọ nínú Kristi, èmi kò ṣèké, ọkàn mi sì ń jẹ́ mi ní ẹ̀rí nínú Ẹ̀mí Mímọ́.
Ninchova icha yelweli mwa Klisite. Saninchova uvudesi, ni nyievonelo nchengo nchikhumbula paninie nune mumepo umbalanche,
2 Pé mo ní ìbìnújẹ́ púpọ̀, àti ìkáàánú ìgbà gbogbo ni ọkàn mi.
Ukhuta khulinulusu valo uluvaha nuluvavo ulusalwisila ngati munumbula yango.
3 Nítorí mo fẹ́rẹ lè gbàdúrà pé kí èmi tìkára mi kúrò lọ́dọ̀ Kristi nítorí àwọn ará mi, àwọn ìbátan mi nípa ti ara.
Ukhuta nale ninogwe une nie mwene ukhukotoliwa nu khutengiwa patali nu Klisite khunogwa ya valokolo lwango, uvuvahwani nune khimbili.
4 Àwọn ẹni tí i ṣe Israẹli; tí àwọn ẹni tí ìsọdọmọ í ṣe, àti ògo, àti májẹ̀mú, àti ìfúnilófin, àti ìsìn Ọlọ́run, àti àwọn ìlérí.
Avene vanya Israeli, uvalivumbikhe vana, va vuvalanche, nu lwokhelo lwa lutagilo, ukhwisa ya khwa Nguluve nu lwokhelo.
5 Tí ẹni tí àwọn Baba í ṣe, àti láti ọ̀dọ̀ àwọn ẹni tí Kristi ti wá nípa ti ara, ẹni tí ó borí ohun gbogbo, Ọlọ́run olùbùkún láéláé. Àmín. (aiōn g165)
Avene vuvalongonchi u Klisite wa inchile kwu lisima ukhofwala umbili ugu - umwene vi Nguluve va fyoni. Navope agini vwage imiaka. Amina. (aiōn g165)
6 Ṣùgbọ́n kì í ṣe pé nítorí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run di asán. Kì í sá í ṣe gbogbo àwọn tí ó ti inú Israẹli wá, àwọn ni Israẹli.
Khange sakhukhuta ulwidihano lwa Nguluve lukemilwe ukhutimila. Ulwakhuva sakhilo munu uviavile inya Israeli vi muIsrael lweli.
7 Bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe pé, nítorí wọ́n jẹ́ irú-ọmọ Abrahamu, gbogbo wọn ni ọmọ. Ní ọ̀nà mìíràn, “Nínú Isaaki ni a ó ti pe irú-ọmọ rẹ̀.”
Ate ne khikhipapo kya Abrahamu ukhuva vana va mwene lweli, “Pwu ukhugendela kwa Isaka ikhipago kyoko khikhwelangiwa.”
8 Èyí nì ni pé, kì í ṣe àwọn ọmọ nípa ti ara ni ọmọ Ọlọ́run, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ ìlérí ni a kà ní irú-ọmọ.
Ukhuta avana va mbili savana va Nguluve. Pwu avanu va lwidihano viloliwa ukhuva khipapo.
9 Nítorí ọ̀rọ̀ ìlérí ni èyí: “Ní ìwòyí àmọ́dún ni èmi yóò wá, Sara yóò sì ní ọmọ ọkùnrin.”
Uhwakhuva ili lyu limenyu lya lwidiheno: “Mwu misinkhi haya nikhwincha, nu Sara iva nu mwana.”
10 Kì í sì í ṣe kìkì èyí, ṣùgbọ́n nígbà tí Rebeka pẹ̀lú lóyún fún ẹnìkan, fún Isaaki baba wa.
Salili vuvule, nayu Rebeka ukhukhava unchigo khu munu yumo, u Isaka udada vitu-
11 Nítorí nígbà tí kò tí ì bí àwọn ọmọ náà, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò tí ì ṣe rere tàbí búburú—kí ìpinnu Ọlọ́run nípa ti ìyànfẹ́ kí ó lè dúró,
Ukhuta avana vakhasigalile ukhu holiwa khange sakha vomba imbombo yoyoni inonu apange imbivi, apange uvunogwe wa Nguluve ukhukongana nu vuhale wime, sio khu mbombo, ulwakhuva ukuta.
12 kì í ṣe nípa ti iṣẹ́, bí kò ṣe ti ẹni tí ń peni—a ti sọ fún un pé, “Ẹ̀gbọ́n ni yóò máa sin àbúrò.”
Lyanchovile khu mwene, “Umbaha ikhumbombela udebe.”
13 Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé, “Jakọbu ni mo fẹ́ràn, ṣùgbọ́n Esau ni mo kórìíra.”
Nduvuyisimbiwe: U Yakobo naaganile, pwu Esau ansulile.”
14 Ǹjẹ́ àwa yóò ha ti wí? Àìṣòdodo ha wà lọ́dọ̀ Ọlọ́run bí? Kí a má ri!
Pwu lino pwu twinchova ikhikhi? Khuli vuvivi khwa Nguluve? Ata.
15 Nítorí ó wí fún Mose pé, “Èmi ó ṣàánú fún ẹni tí èmi yóò ṣàánú fún, èmi yóò sì ṣe ìyọ́nú fún ẹni tí èmi yóò ṣe ìyọ́nú fún.”
Ulwakuva inchova kwa Mose, “Niva nikhisa kwulo uvinikwu nsyikhela, niva nu lusyikhilo kwa ula uviya nikwu n'syikhila, khange niva huruma khu yule uvinikwusyikila.
16 Ǹjẹ́ bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe ti ẹni tí ó fẹ́, kì í sì í ṣe ti ẹni tí ń sáré, bí kò ṣe ti Ọlọ́run tí ń ṣàánú.
Pwu lino sayivile umwene uviinogwa khange sa lwakuva inyile uviivonesya ikhisa.
17 Nítorí ìwé mímọ́ wí fún Farao pé, “Nítorí èyí náà ni mo ṣe gbé ọ dìde, kí èmi kí ó le fi agbára mi hàn lára rẹ, àti kí a bá à le máa ròyìn orúkọ mi ká gbogbo ayé.”
Ulwakuva uvusimbe vwita kwa Farao, “Khuvunogwe uvu uvuvamana nikha khwimikha une nivonesye amakha gango khulyuve, nukuva ilitavwa lyango linchovivwage ikhilunga kyoni.”
18 Nítorí náà ni ó ṣe ń ṣàánú fún ẹni tí ó wù ú, ẹni tí ó wù ú a sì mú ní ọkàn le.
Pwu lino uNguluve iva ni khisa khumunu yoni uvyaganile, na uvyaganile, ikhumbikhe ukhuvanya ngani.
19 Ìwọ ó sì wí fún mi pé, “Kín ni ó ha tún bá ni wí sí? Nítorí ta ni ó ń de ìfẹ́ rẹ lọ́nà?”
Pwu yawita khulione, “Pwu khikhi vupilola uvuvivi? Pwu alikhi uviegumilinche uvunogwe vwa mwene?”
20 Bẹ́ẹ̀ kọ́, ìwọ ènìyàn, tà ni ìwọ tí ń dá Ọlọ́run lóhùn? “Ohun tí a mọ, a ha máa wí fún ẹni tí ó mọ ọ́n pé, ‘Èéṣe tí ìwọ fi mọ mi báyìí?’”
Vi munu veve veni vi vukhumbulo vunge uNguluve? vwiwesya ukhulumanye ikhinu ikyu vumbile ukunchova kwu munu uvya khivumbile, “Khekhi ukhambikhile evwo une?”
21 Amọ̀kòkò kò ha ni agbára lórí amọ̀, nínú ìṣù kan náà láti ṣe apá kan nínú ohun èlò sí ọlá, àti apá kan nínú ohun èlò sí àìlọ́lá?
Khukhu uvivumba inchila vwa yelweli kwu ng'anga ukhuvumba ikhivombelo ukhumana nu ng'anga gula gule, ni khyombo khinge khu mbombo yi figono fyoni?
22 Ǹjẹ́ bí Ọlọ́run bá fẹ́ fi ìbínú rẹ̀ hàn ń kọ́? Tí ó sì fẹ́ sọ agbára rẹ̀ di mí mọ̀, tí ó sì mú sùúrù púpọ̀ fún àwọn ohun èlò ìbínú tí a ṣe fún ìparun.
Ndakhekhi ingave, uNguluve, uvi alinuvunu vwa khuvonesya uvuvivi vwa uvuvivi vwa mwene nu khuvomba ne makhaga mwene ukhuvoneka, akhanogile ukwiyumilinche, iatbu iyuyivikhiwe kwa khuyancho?
23 Àti kí ó lè sọ ọ̀rọ̀ ògo rẹ̀ di mí mọ̀ lára àwọn ohun èlò àánú tí ó ti pèsè ṣáájú fún ògo.
Ndakhikhi ingave avombile evo avonesye uwingi vwa vulancha vwa mwene kwu fyombo fya khisa, ifyo ifi fikhavikhilwe kwu vuvalanche?
24 Àní àwa, tí ó ti pè, kì í ṣe nínú àwọn Júù nìkan, ṣùgbọ́n nínú àwọn Kèfèrí pẹ̀lú?
Ndakhikhi ingave akhavombile khuvanu va khilunga?
25 Bí ó ti wí pẹ̀lú ní Hosea pé, “Èmi ó pe àwọn tí kì í ṣe ènìyàn mi, ní ‘ènìyàn mi’, àti ẹni tí kí í ṣe àyànfẹ́ ní ‘àyànfẹ́.’”
Nduvwichova khange khwa Hosea: “Nikhuvilanga avanu vango uvuvale savanu vangu nu ngane va mwene uvisakhe ngane.
26 Yóò sì ṣe, “Ní ibi ti a gbé ti sọ fún wọn pé, ‘Ẹ̀yin kì í ṣe ènìyàn mi,’ níbẹ̀ ni a ó gbé pè wọ́n ní ‘ọmọ Ọlọ́run alààyè.’”
Khange yayiva ukhuta pala upwa khanchovivivwe kuvene, 'Umwe samlivanu vango,' pala vikhilangiwa 'vana va Nguluve umwumi.'”
27 Isaiah sì kígbe nítorí Israẹli pé: “Bí iye àwọn ọmọ Israẹli bá rí bí iyanrìn Òkun, apá kan ni ó gbàlà.
Uyisaya ilila ukhukongano ni Israeli, “Ingave imbalilo ncha vana va Israeli ncha chivenchage ndu nganga ugwa nyanja, igiva gu melagalila legu giva masigalila uvu yavipokiwa.
28 Nítorí Olúwa yóò mú ọ̀rọ̀ rẹ̀ ṣẹ lórí ilẹ̀ ayé, yóò parí rẹ̀, yóò sì ké e kúrò ní òdodo.”
Ulwakhuva unkuludeva ayikulitola ilimenyu lya mwene pakhanya pakhilunga, khimbivi nu uvukwilanile.
29 Àti bí Isaiah ti wí tẹ́lẹ̀: “Bí kò ṣe bí Olúwa àwọn Ọmọ-ogun ti fi irú-ọmọ sílẹ̀ fún wa, àwa ìbá ti dàbí Sodomu, a bá sì ti sọ wá dàbí Gomorra.”
Nduvu Isaya vu anchovile, “Ingave unkuludeva vavasikhali sa khatulekhe khunsana kwu khivumbukho kyito, tukhale twiva ndu Sodoma, na tuvombivwa nda Mgomora.
30 Ǹjẹ́ kí ni àwa ó ha wí? Pé àwọn Kèfèrí, tí kò lépa òdodo, ọwọ́ wọn tẹ òdodo, ṣùgbọ́n òdodo tí ó ti inú ìgbàlà wá ni.
twita khekhi lino? Ukhuta avanu va nkilunga uvu savalikhulonda uvwa yilweli, uvwa yilweli wa lwidincho.
31 Ṣùgbọ́n Israẹli ti ń lépa òfin òdodo, ọwọ́ wọn kò tẹ òfin òdodo.
Pwu lino unya Israeli, vyalikhulobda ululagilo lwe vwa yilweli sakhefikha.
32 Nítorí kí ni? Nítorí wọn kò wá a nípa ìgbàgbọ́, ṣùgbọ́n bí ẹni pé nípa iṣẹ́ òfin. Nítorí wọn kọsẹ̀ lára òkúta ìkọ̀sẹ̀ ni.
Khekhi sayikhale ivwo? Ulwakhuva savalikhu nu lwidikho, valikholonde kwu mbombo. Vakhi khuvancha pakyanya paliwe ilya kwi kuvancho,
33 Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé, “Kíyèsi, mo gbé òkúta ìkọ̀sẹ̀ kalẹ̀ ní Sioni àti àpáta tí ó mú wọn ṣubú, ẹnikẹ́ni ti ó bá sì gbà a gbọ́, ojú kì yóò tì í.”
Nduvuyivile yisimbiwe, “Lola, nivikhile ilivwe lya kwi kuvancha mSayuni nu umwene uviikhwidikha salasukha.”

< Romans 9 >