< Romans 9 >
1 Òtítọ́ ni èmi ń sọ nínú Kristi, èmi kò ṣèké, ọkàn mi sì ń jẹ́ mi ní ẹ̀rí nínú Ẹ̀mí Mímọ́.
Krstosn arikoniye t keewiri, kooratse, S'ayn shayiron t nibonúwere tkorawok'o taash gawirwe.
2 Pé mo ní ìbìnújẹ́ púpọ̀, àti ìkáàánú ìgbà gbogbo ni ọkàn mi.
Een shiyanonat k'ut'eraw kic'on t nibotse fa'ee,
3 Nítorí mo fẹ́rẹ lè gbàdúrà pé kí èmi tìkára mi kúrò lọ́dọ̀ Kristi nítorí àwọn ará mi, àwọn ìbátan mi nípa ti ara.
Meetson t jag wotts tjiruwotssha err taa Krstosatse k'aleyar Ik' c'asho tiyats b́bodink'e shunfee b́teshi.
4 Àwọn ẹni tí i ṣe Israẹli; tí àwọn ẹni tí ìsọdọmọ í ṣe, àti ògo, àti májẹ̀mú, àti ìfúnilófin, àti ìsìn Ọlọ́run, àti àwọn ìlérí.
Boye Israe'el ashuwotsiye, na'ok'o wotonat mangi wuliyo nemono b́imi, aron Ik'o bo ik'itywok'ono b́kitsi, b́ jangits keewo bíimi.
5 Tí ẹni tí àwọn Baba í ṣe, àti láti ọ̀dọ̀ àwọn ẹni tí Kristi ti wá nípa ti ara, ẹni tí ó borí ohun gbogbo, Ọlọ́run olùbùkún láéláé. Àmín. (aiōn )
Amants nihwotswere bokne, Krstos meetson b́wáá bo naarotsne, bíye jamoniyere dambe. Bíwere dúre dúrosh deeretso Izar Izeweriye. Amen! (aiōn )
6 Ṣùgbọ́n kì í ṣe pé nítorí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run di asán. Kì í sá í ṣe gbogbo àwọn tí ó ti inú Israẹli wá, àwọn ni Israẹli.
Wotowa eree Ik' aap'tso wonere etaliye, Israe'el naar jamwots ari Israe'el ashnaliye.
7 Bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe pé, nítorí wọ́n jẹ́ irú-ọmọ Abrahamu, gbogbo wọn ni ọmọ. Ní ọ̀nà mìíràn, “Nínú Isaaki ni a ó ti pe irú-ọmọ rẹ̀.”
Mank'o Abraham naar jamo Abraham nanaúwotsiye etaliye. Ik'o Abrahamsh «N naaro b́ keshetiye Yisak'ne» bíettsoshe,
8 Èyí nì ni pé, kì í ṣe àwọn ọmọ nípa ti ara ni ọmọ Ọlọ́run, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ ìlérí ni a kà ní irú-ọmọ.
Mansh meetson shuwetswots Ik' nanaúwotsiyaliye, ernmó naaro wotar taawetuwots Ik'o Abrahamsh b́jangitsok'on shuwetswots s'uziye.
9 Nítorí ọ̀rọ̀ ìlérí ni èyí: “Ní ìwòyí àmọ́dún ni èmi yóò wá, Sara yóò sì ní ọmọ ọkùnrin.”
Hanuwere Ik'o b́jangits aap'otse «Hambets naton hank'o aawon weetuwe, Sara nungush na'o shuwitwane» etke b́teshi.
10 Kì í sì í ṣe kìkì èyí, ṣùgbọ́n nígbà tí Rebeka pẹ̀lú lóyún fún ẹnìkan, fún Isaaki baba wa.
Man mec'ro b́ woterawo Rbk'aa naruwotssh niho wottsosh Yisak'sh nungush nana'a maatúwotsi b maac'ro,
11 Nítorí nígbà tí kò tí ì bí àwọn ọmọ náà, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò tí ì ṣe rere tàbí búburú—kí ìpinnu Ọlọ́run nípa ti ìyànfẹ́ kí ó lè dúró,
Ik'i marat' marat'o finon b́woterawo b́s'eegon b́woto kitsosh git nan'úwots boshuwewonat gondonowere sheengonowere bok'aloniyere shino
12 kì í ṣe nípa ti iṣẹ́, bí kò ṣe ti ẹni tí ń peni—a ti sọ fún un pé, “Ẹ̀gbọ́n ni yóò máa sin àbúrò.”
Ik'o Rbk'ash «Eenfo múk'efosh keewek wotituwe» bí eti.
13 Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé, “Jakọbu ni mo fẹ́ràn, ṣùgbọ́n Esau ni mo kórìíra.”
Manúwere «Yak'obi shunre Esawunmó shit're» ett guut'etsok'one.
14 Ǹjẹ́ àwa yóò ha ti wí? Àìṣòdodo ha wà lọ́dọ̀ Ọlọ́run bí? Kí a má ri!
Eshe eege noeteti? Ik'o boga bogshirwe eronowa? B́jamon mank'o woteratse!
15 Nítorí ó wí fún Mose pé, “Èmi ó ṣàánú fún ẹni tí èmi yóò ṣàánú fún, èmi yóò sì ṣe ìyọ́nú fún ẹni tí èmi yóò ṣe ìyọ́nú fún.”
Ik'oniye Musesh «Bísh doosh tgeyruwosh doowituwe, bísh maac' k'ewo tgeyiruwoshowere maac'o k'ewituwe» etre.
16 Ǹjẹ́ bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe ti ẹni tí ó fẹ́, kì í sì í ṣe ti ẹni tí ń sáré, bí kò ṣe ti Ọlọ́run tí ń ṣàánú.
Eshe Ik'i marat'o b́daatset ash shunonat ash finon b́woterawo Ik' dowon b́wottsatsne.
17 Nítorí ìwé mímọ́ wí fún Farao pé, “Nítorí èyí náà ni mo ṣe gbé ọ dìde, kí èmi kí ó le fi agbára mi hàn lára rẹ, àti kí a bá à le máa ròyìn orúkọ mi ká gbogbo ayé.”
Manatse tuutson S'ayin mas'aafotse Gbs' nugúsosh «Neen tiango kitsr tshútsonowere dats jamatse b́daneetuwok'o woshosh neen naashiyire» ett aap'etso guut'ere.
18 Nítorí náà ni ó ṣe ń ṣàánú fún ẹni tí ó wù ú, ẹni tí ó wù ú a sì mú ní ọkàn le.
Mansh eshe Ik'o b́shuntsosh maac'o k'ewefe, b́shuntsonowere k'el kúp'etso woshituwe.
19 Ìwọ ó sì wí fún mi pé, “Kín ni ó ha tún bá ni wí sí? Nítorí ta ni ó ń de ìfẹ́ rẹ lọ́nà?”
Eshe «Ik'i shunts keewo k'efosh konuwor falratse, béré bí ashuwots bo shuntso bo fintsosh eegishe boon b́ b́s'aamiyiri» err taan aato falfete.
20 Bẹ́ẹ̀ kọ́, ìwọ ènìyàn, tà ni ìwọ tí ń dá Ọlọ́run lóhùn? “Ohun tí a mọ, a ha máa wí fún ẹni tí ó mọ ọ́n pé, ‘Èéṣe tí ìwọ fi mọ mi báyìí?’”
Nee ashono! Ik'onton mooshosh eegoneya nfali? Shalon dozets k'ac'o bín dooztsosh «Eegishe hank'o kaldek'at taan ndoozi?» etosh falituwa?
21 Amọ̀kòkò kò ha ni agbára lórí amọ̀, nínú ìṣù kan náà láti ṣe apá kan nínú ohun èlò sí ọlá, àti apá kan nínú ohun èlò sí àìlọ́lá?
Eshe shal wozirwo iknaari shali tok'ootse k'ac iko mangosh, k'oshonowere ketts finosh woshde wozosh alo deshatsá?
22 Ǹjẹ́ bí Ọlọ́run bá fẹ́ fi ìbínú rẹ̀ hàn ń kọ́? Tí ó sì fẹ́ sọ agbára rẹ̀ di mí mọ̀, tí ó sì mú sùúrù púpọ̀ fún àwọn ohun èlò ìbínú tí a ṣe fún ìparun.
Ik'o b́fayo kitsosho bíangonowere bek'shosh geeyat t'afiyosh k'antsuwotsi fayi k'ac'uwotsi ayoto k'amare wotiyal eendani?
23 Àti kí ó lè sọ ọ̀rọ̀ ògo rẹ̀ di mí mọ̀ lára àwọn ohun èlò àánú tí ó ti pèsè ṣáájú fún ògo.
Han b́ k'aluwere shin mangosh b́k'anitso sheeng b́woto dek'ets k'ac'uwotssh b́mangi ayo kitsoshe.
24 Àní àwa, tí ó ti pè, kì í ṣe nínú àwọn Júù nìkan, ṣùgbọ́n nínú àwọn Kèfèrí pẹ̀lú?
Sheeng b́ woto dek'ets k'ac'uwotsnmó ayhudiwots mec'rotse b́woterawon Ik'i ash woterawwotsitsnowere noon s'eegree.
25 Bí ó ti wí pẹ̀lú ní Hosea pé, “Èmi ó pe àwọn tí kì í ṣe ènìyàn mi, ní ‘ènìyàn mi’, àti ẹni tí kí í ṣe àyànfẹ́ ní ‘àyànfẹ́.’”
Hanwere nebiyiyo Hose'n hank'o eteetsok'one, «Tiash teyawuwotsne ‹Tiashuwotsi› err s'eegetuwe, Shuneerawu ashuwotsnowere ‹Shuneeka› err s'eegetuwe,
26 Yóò sì ṣe, “Ní ibi ti a gbé ti sọ fún wọn pé, ‘Ẹ̀yin kì í ṣe ènìyàn mi,’ níbẹ̀ ni a ó gbé pè wọ́n ní ‘ọmọ Ọlọ́run alààyè.’”
Itiye ‹Tiashuwots itnaaliye› eteets beyokoke ‹Beyat beets Ik'o nanaúwotsi› err boon s'eegetuwe.»
27 Isaiah sì kígbe nítorí Israẹli pé: “Bí iye àwọn ọmọ Israẹli bá rí bí iyanrìn Òkun, apá kan ni ó gbàlà.
Isayasuwere Israe'el jangosh hank'o eton b́ k'ááro eenshdek'tine b́keewi, «Isra'el nanaúwots taawo aats k'aritsi shiyok'o dab bíayiyaloru boyitse kashituwots múk'nee.
28 Nítorí Olúwa yóò mú ọ̀rọ̀ rẹ̀ ṣẹ lórí ilẹ̀ ayé, yóò parí rẹ̀, yóò sì ké e kúrò ní òdodo.”
Doonzo b́ ja'arawo kááronat s'eenon bí angsho imetwe.»
29 Àti bí Isaiah ti wí tẹ́lẹ̀: “Bí kò ṣe bí Olúwa àwọn Ọmọ-ogun ti fi irú-ọmọ sílẹ̀ fún wa, àwa ìbá ti dàbí Sodomu, a bá sì ti sọ wá dàbí Gomorra.”
Mank'owere Isayas «Dari jirwotssh doonzo shooko noosh oriyo b́k'azink'ere Sedom kituk'o wotiyank'one b́teshi Gemor kitukok'o wotiyank'one b́teshi» ett shin shin keewure.
30 Ǹjẹ́ kí ni àwa ó ha wí? Pé àwọn Kèfèrí, tí kò lépa òdodo, ọwọ́ wọn tẹ òdodo, ṣùgbọ́n òdodo tí ó ti inú ìgbàlà wá ni.
Eshe eege no keewiti? Kááwi weero sha'erawu Ik'i ash woterawwots kááw woto bodaatsi, kááwo wotonwere amanar daatsetuwoniye.
31 Ṣùgbọ́n Israẹli ti ń lépa òfin òdodo, ọwọ́ wọn kò tẹ òfin òdodo.
Ernmó kááw woto daatsit nemo shuuts sha'at teshts Isra'elots, nemo s'eentsosh bomawutsotse kááwok boratsne.
32 Nítorí kí ni? Nítorí wọn kò wá a nípa ìgbàgbọ́, ṣùgbọ́n bí ẹni pé nípa iṣẹ́ òfin. Nítorí wọn kọsẹ̀ lára òkúta ìkọ̀sẹ̀ ni.
«Eegoshe kááwok bodobok'azi?» eteyala bo kááw wottso daatsosh boge amanon b́woterawon finon b́wottsotsne, manshe t'ugwotsn bo k'is'eyi.
33 Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé, “Kíyèsi, mo gbé òkúta ìkọ̀sẹ̀ kalẹ̀ ní Sioni àti àpáta tí ó mú wọn ṣubú, ẹnikẹ́ni ti ó bá sì gbà a gbọ́, ojú kì yóò tì í.”
Manuwere «Hambe! ashuwotsi k'is'iru shútso S'iyonits beezree, Shútsanuwere ashuwotsi k'ic'de'er dikitu s'aloniye, Bín amanituwonmó jiitsratse» ett guut'etsok'one.