< Romans 16 >

1 Mo fi Febe arábìnrin wa le yin lọ́wọ́, ẹni tí ó jẹ́ díákónì nínú ìjọ tí ó wà ní Kenkerea.
ཀིཾཀྲཱིཡཱནགརཱིཡདྷརྨྨསམཱཛསྱ པརིཙཱརིཀཱ ཡཱ ཕཻབཱིནཱམིཀཱསྨཱཀཾ དྷརྨྨབྷགིནཱི ཏསྱཱཿ ཀྲྀཏེ྅ཧཾ ཡུཥྨཱན྄ ནིཝེདཡཱམི,
2 Mo rọ̀ yín kí ẹ gbà á ní orúkọ Olúwa, bí ó ti yẹ fún àwọn ènìyàn mímọ́, kí ẹ̀yin kí ó sì ràn án lọ́wọ́ ní gbogbo ọ̀nà, nítorí pé òun jẹ́ olùrànlọ́wọ́ fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn àti fún èmi náà pẹ̀lú.
ཡཱུཡཾ ཏཱཾ པྲབྷུམཱཤྲིཏཱཾ ཝིཛྙཱཡ ཏསྱཱ ཨཱཏིཐྱཾ པཝིཏྲལོཀཱརྷཾ ཀུརུདྷྭཾ, ཡུཥྨཏྟསྟསྱཱ ཡ ཨུཔཀཱརོ བྷཝིཏུཾ ཤཀྣོཏི ཏཾ ཀུརུདྷྭཾ, ཡསྨཱཏ྄ ཏཡཱ བཧཱུནཱཾ མམ ཙོཔཀཱརཿ ཀྲྀཏཿ།
3 Ẹ kí Priskilla àti Akuila, àwọn tí ó ti jẹ́ alábáṣiṣẹ́pọ̀ mi nínú Kristi Jesu.
ཨཔརཉྩ ཁྲཱིཥྚསྱ ཡཱིཤོཿ ཀརྨྨཎི མམ སཧཀཱརིཎཽ མམ པྲཱཎརཀྵཱརྠཉྩ སྭཔྲཱཎཱན྄ པཎཱིཀྲྀཏཝནྟཽ ཡཽ པྲིཥྐིལླཱཀྐིལཽ ཏཽ མམ ནམསྐཱརཾ ཛྙཱཔཡདྷྭཾ།
4 Àwọn tí wọ́n ti fi ẹ̀mí wọn wéwu nítorí mi. Kì í ṣe èmi nìkan àti gbogbo àwọn ìjọ àwọn aláìkọlà ń dúpẹ́ lọ́wọ́ wọn.
ཏཱབྷྱཱམ྄ ཨུཔཀཱརཱཔྟིཿ ཀེཝལཾ མཡཱ སྭཱིཀརྟྟཝྱེཏི ནཧི བྷིནྣདེཤཱིཡཻཿ སཪྻྭདྷརྨྨསམཱཛཻརཔི།
5 Kí ẹ sì kí ìjọ tí ń péjọpọ̀ ní ilé wọn. Ẹ kí Epenetu ọ̀rẹ́ mi ọ̀wọ́n, òun ni ẹni àkọ́kọ́ tí ó di ti Kristi ní orílẹ̀-èdè Asia.
ཨཔརཉྩ ཏཡོ རྒྲྀཧེ སྠིཏཱན྄ དྷརྨྨསམཱཛལོཀཱན྄ མམ ནམསྐཱརཾ ཛྙཱཔཡདྷྭཾ། ཏདྭཏ྄ ཨཱཤིཡཱདེཤེ ཁྲཱིཥྚསྱ པཀྵེ པྲཐམཛཱཏཕལསྭརཱུཔོ ཡ ཨིཔེནིཏནཱམཱ མམ པྲིཡབནྡྷུསྟམཔི མམ ནམསྐཱརཾ ཛྙཱཔཡདྷྭཾ།
6 Ẹ kí Maria, ẹni tí ó ṣe làálàá púpọ̀ lórí wa.
ཨཔརཾ བཧུཤྲམེཎཱསྨཱན྄ ཨསེཝཏ ཡཱ མརིཡམ྄ ཏཱམཔི ནམསྐཱརཾ ཛྙཱཔཡདྷྭཾ།
7 Ẹ kí Androniku àti Junia, àwọn ìbátan mi tí wọ́n wà ní ẹ̀wọ̀n pẹ̀lú mi. Àwọn wọ̀nyí ní ìtayọ láàrín àwọn aposteli, wọ́n sì ti wà nínú Kristi ṣáájú mi.
ཨཔརཉྩ པྲེརིཏེཥུ ཁྱཱཏཀཱིརྟྟཱི མདགྲེ ཁྲཱིཥྚཱཤྲིཏཽ མམ སྭཛཱཏཱིཡཽ སཧབནྡིནཽ ཙ ཡཱཝཱནྡྲནཱིཀཡཱུནིཡཽ ཏཽ མམ ནམསྐཱརཾ ཛྙཱཔཡདྷྭཾ།
8 Ẹ kí Ampliatu, ẹni tí ó jẹ́ olùfẹ́ mi nínú Olúwa.
ཏཐཱ པྲབྷཽ མཏྤྲིཡཏམམ྄ ཨཱམྤླིཡམཔི མམ ནམསྐཱརཾ ཛྙཱཔཡདྷྭཾ།
9 Ẹ kí Urbani, alábáṣiṣẹ́pọ̀ wa nínú Kristi àti olùfẹ́ mi ọ̀wọ́n Staki.
ཨཔརཾ ཁྲཱིཥྚསེཝཱཡཱཾ མམ སཧཀཱརིཎམ྄ ཨཱུརྦྦཱཎཾ མམ པྲིཡཏམཾ སྟཱཁུཉྩ མམ ནམསྐཱརཾ ཛྙཱཔཡདྷྭཾ།
10 Ẹ kí Apelle, ẹni tí a mọ̀ dájú nínú Kristi. Ẹ kí gbogbo àwọn ará nílé Aristobulu.
ཨཔརཾ ཁྲཱིཥྚེན པརཱིཀྵིཏམ྄ ཨཱཔིལླིཾ མམ ནམསྐཱརཾ ཝདཏ, ཨཱརིཥྚབཱུལསྱ པརིཛནཱཾཤྩ མམ ནམསྐཱརཾ ཛྙཱཔཡདྷྭཾ།
11 Ẹ kí Herodioni, ìbátan mi. Ẹ kí gbogbo àwọn ará nílé Narkissu tí wọ́n wá nínú Olúwa.
ཨཔརཾ མམ ཛྙཱཏིཾ ཧེརོདིཡོནཾ མམ ནམསྐཱརཾ ཝདཏ, ཏཐཱ ནཱརྐིསསྱ པརིཝཱརཱཎཱཾ མདྷྱེ ཡེ པྲབྷུམཱཤྲིཏཱསྟཱན྄ མམ ནམསྐཱརཾ ཝདཏ།
12 Ẹ kí Trifena àti Trifosa, àwọn obìnrin tí wọ́n ṣe iṣẹ́ takuntakun nínú Olúwa. Ẹ kí Persi ọ̀rẹ́ mi ọ̀wọ́n, obìnrin mìíràn tí ó ṣe iṣẹ́ takuntakun nínú Olúwa.
ཨཔརཾ པྲབྷོཿ སེཝཱཡཱཾ པརིཤྲམཀཱརིཎྱཽ ཏྲུཕེནཱཏྲུཕོཥེ མམ ནམསྐཱརཾ ཝདཏ, ཏཐཱ པྲབྷོཿ སེཝཱཡཱམ྄ ཨཏྱནྟཾ པརིཤྲམཀཱརིཎཱི ཡཱ པྲིཡཱ པརྵིསྟཱཾ ནམསྐཱརཾ ཛྙཱཔཡདྷྭཾ།
13 Ẹ kí Rufusi, ẹni tí a yàn nínú Olúwa, àti ìyá rẹ̀ àti ẹni tí ó ti jẹ́ ìyá fún èmi náà pẹ̀lú.
ཨཔརཾ པྲབྷོརབྷིརུཙིཏཾ རཱུཕཾ མམ དྷརྨྨམཱཏཱ ཡཱ ཏསྱ མཱཏཱ ཏཱམཔི ནམསྐཱརཾ ཝདཏ།
14 Ẹ kí Asinkritu, Flegoni, Herma, Patroba, Hermesi àti àwọn arákùnrin àti arábìnrin tí ó wà pẹ̀lú wọn.
ཨཔརམ྄ ཨསུཾཀྲྀཏཾ ཕླིགོནཾ ཧརྨྨཾ པཱཏྲབཾ ཧརྨྨིམ྄ ཨེཏེཥཱཾ སངྒིབྷྲཱཏྲྀགཎཉྩ ནམསྐཱརཾ ཛྙཱཔཡདྷྭཾ།
15 Ẹ kí Filologu, àti Julia, Nereu, àti arábìnrin rẹ̀, àti Olimpa, àti gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́ tí ó wà pẹ̀lú wọn.
ཨཔརཾ ཕིལལགོ ཡཱུལིཡཱ ནཱིརིཡསྟསྱ བྷགིནྱལུམྤཱ ཙཻཏཱན྄ ཨེཏཻཿ སཱརྡྡྷཾ ཡཱཝནྟཿ པཝིཏྲལོཀཱ ཨཱསཏེ ཏཱནཔི ནམསྐཱརཾ ཛྙཱཔཡདྷྭཾ།
16 Ẹ fi ìfẹnukonu mímọ́ kí ara yín. Gbogbo ìjọ Kristi kí yín.
ཡཱུཡཾ པརསྤརཾ པཝིཏྲཙུམྦནེན ནམསྐུརུདྷྭཾ། ཁྲཱིཥྚསྱ དྷརྨྨསམཱཛགཎོ ཡུཥྨཱན྄ ནམསྐུརུཏེ།
17 Èmí rọ̀ yín, ara, kí ẹ máa sọ àwọn tí ń fa ìyapa, àti àwọn tí ń mú ohun ìkọ̀sẹ̀ wá sí ọ̀nà yín, èyí tí ó lòdì sí ẹ̀kọ́ tí ẹ̀yin kọ́. Ẹ yà kúrò ní ọ̀dọ̀ wọn.
ཧེ བྷྲཱཏརོ ཡུཥྨཱན྄ ཝིནཡེ྅ཧཾ ཡུཥྨཱབྷི ཪྻཱ ཤིཀྵཱ ལབྡྷཱ ཏཱམ྄ ཨཏིཀྲམྱ ཡེ ཝིཙྪེདཱན྄ ཝིགྷྣཱཾཤྩ ཀུཪྻྭནྟི ཏཱན྄ ནིཤྩིནུཏ ཏེཥཱཾ སངྒཾ ཝརྫཡཏ ཙ།
18 Nítorí irú àwọn ẹni bẹ́ẹ̀ kò sin Kristi Olúwa wa, bí kò ṣe ikùn ara wọn. Nípa ọ̀rọ̀ rere àti ọ̀rọ̀ dídùndídùn ni wọ́n fi ń yí àwọn aláìmọ̀kan ní ọkàn padà.
ཡཏསྟཱདྲྀཤཱ ལོཀཱ ཨསྨཱཀཾ པྲབྷོ ཪྻཱིཤུཁྲཱིཥྚསྱ དཱསཱ ཨིཏི ནཧི ཀིནྟུ སྭོདརསྱཻཝ དཱསཱཿ; ཨཔརཾ པྲཎཡཝཙནཻ རྨདྷུརཝཱཀྱཻཤྩ སརལལོཀཱནཱཾ མནཱཾསི མོཧཡནྟི།
19 Nítorí ìgbọ́ràn yín tànkálẹ̀ dé ibi gbogbo, nítorí náà mo ní ayọ̀ lórí yín; ṣùgbọ́n èmi fẹ́ kí ẹ jẹ́ ọlọ́gbọ́n sí ohun tí ó ṣe rere, kí ẹ sì ṣe òpè sí ohun tí í ṣe búburú.
ཡུཥྨཱཀམ྄ ཨཱཛྙཱགྲཱཧིཏྭཾ སཪྻྭཏྲ སཪྻྭཻ རྫྙཱཏཾ ཏཏོ྅ཧཾ ཡུཥྨཱསུ སཱནནྡོ྅བྷཝཾ ཏཐཱཔི ཡཱུཡཾ ཡཏ྄ སཏྫྙཱནེན ཛྙཱནིནཿ ཀུཛྙཱནེ ཙཱཏཏྤརཱ བྷཝེཏེཏི མམཱབྷིལཱཥཿ།
20 Ọlọ́run àlàáfíà yóò sì tẹ Satani mọ́lẹ̀ ní àtẹ́lẹsẹ̀ yín ní lọ́ọ́lọ́ọ́ yìí. Oore-ọ̀fẹ́ Jesu Kristi Olúwa wa kí ó wà pẹ̀lú yín.
ཨདྷིཀནྟུ ཤཱནྟིདཱཡཀ ཨཱིཤྭརཿ ཤཻཏཱནམ྄ ཨཝིལམྦཾ ཡུཥྨཱཀཾ པདཱནཱམ྄ ཨདྷོ མརྡྡིཥྱཏི། ཨསྨཱཀཾ པྲབྷུ ཪྻཱིཤུཁྲཱིཥྚོ ཡུཥྨཱསུ པྲསཱདཾ ཀྲིཡཱཏ྄། ཨིཏི།
21 Timotiu alábáṣiṣẹ́ mi, àti Lukiu, àti Jasoni, àti Sosipateru, àwọn ìbátan mi, kí yín.
མམ སཧཀཱརཱི ཏཱིམཐིཡོ མམ ཛྙཱཏཡོ ལཱུཀིཡོ ཡཱསོན྄ སོསིཔཱཏྲཤྩེམེ ཡུཥྨཱན྄ ནམསྐུཪྻྭནྟེ།
22 Èmi Tertiu tí ń kọ lẹ́tà yìí, kí yín nínú Olúwa.
ཨཔརམ྄ ཨེཏཏྤཏྲལེཁཀསྟརྟྟིཡནཱམཱཧམཔི པྲབྷོ རྣཱམྣཱ ཡུཥྨཱན྄ ནམསྐརོམི།
23 Gaiusi, ẹni tí èmi àti gbogbo ìjọ gbádùn ìtọ́jú wa tí ó ṣe náà fi ìkíni ránṣẹ́. Erastu, ẹni tí ó jẹ́ olùtọ́jú ìṣúra ìlú, àti arákùnrin wa Kuartu fi ìkíni wọn ránṣẹ́.
ཏཐཱ ཀྲྀཏྶྣདྷརྨྨསམཱཛསྱ མམ ཙཱཏིཐྱཀཱརཱི གཱཡོ ཡུཥྨཱན྄ ནམསྐརོཏི། ཨཔརམ྄ ཨེཏནྣགརསྱ དྷནརཀྵཀ ཨིརཱསྟཿ ཀྐཱརྟྟནཱམཀཤྩཻཀོ བྷྲཱཏཱ ཏཱཝཔི ཡུཥྨཱན྄ ནམསྐུརུཏཿ།
ཨསྨཱཀཾ པྲབྷུ ཪྻཱིཤུཁྲཱིཥྚཱ ཡུཥྨཱསུ སཪྻྭེཥུ པྲསཱདཾ ཀྲིཡཱཏ྄། ཨིཏི།
25 Ǹjẹ́ fún ẹni tí ó ní agbára láti fi ẹsẹ̀ yín múlẹ̀ nípa ìyìnrere mi àti ìpolongo Jesu Kristi, gẹ́gẹ́ bí ìṣípayá ohun ìjìnlẹ̀ tí a ti pamọ́ láti ìgbà ayérayé, (aiōnios g166)
པཱུཪྻྭཀཱལིཀཡུགེཥུ པྲཙྪནྣཱ ཡཱ མནྟྲཎཱདྷུནཱ པྲཀཱཤིཏཱ བྷཱུཏྭཱ བྷཝིཥྱདྭཱདིལིཁིཏགྲནྠགཎསྱ པྲམཱཎཱད྄ ཝིཤྭཱསེན གྲཧཎཱརྠཾ སདཱཏནསྱེཤྭརསྱཱཛྙཡཱ སཪྻྭདེཤཱིཡལོཀཱན྄ ཛྙཱཔྱཏེ, (aiōnios g166)
26 ṣùgbọ́n, nísinsin yìí, a ti fihàn nípa ìwé mímọ́ àwọn wòlíì, àti gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí Ọlọ́run ayérayé pa, kí gbogbo orílẹ̀-èdè le ní ìgbọ́ràn tí ó wá láti inú ìgbàgbọ́; (aiōnios g166)
ཏསྱཱ མནྟྲཎཱཡཱ ཛྙཱནཾ ལབྡྷྭཱ མཡཱ ཡཿ སུསཾཝཱདོ ཡཱིཤུཁྲཱིཥྚམདྷི པྲཙཱཪྻྱཏེ, ཏདནུསཱརཱད྄ ཡུཥྨཱན྄ དྷརྨྨེ སུསྠིརཱན྄ ཀརྟྟུཾ སམརྠོ ཡོ྅དྭིཏཱིཡཿ (aiōnios g166)
27 kí ògo wà fún Ọlọ́run, ẹnìkan ṣoṣo tí ọgbọ́n í ṣe tirẹ̀ nípa Jesu Kristi títí láé! Àmín. (aiōn g165)
སཪྻྭཛྙ ཨཱིཤྭརསྟསྱ དྷནྱཝཱདོ ཡཱིཤུཁྲཱིཥྚེན སནྟཏཾ བྷཱུཡཱཏ྄། ཨིཏི། (aiōn g165)

< Romans 16 >