< Romans 15 >

1 Àwa tí a jẹ́ alágbára nínú ìgbàgbọ́ yẹ kí ó máa ru ẹrù àìlera àwọn aláìlera, kí a má sì ṣe ohun tí ó wu ara wa.
Eshi atee tetili nedadi tihwaziwa ahweje ulembezu wabhala alembezu, satihwaziwa ahwilole tete.
2 Olúkúlùkù wa gbọdọ̀ máa ṣe ohun tí ó wu ọmọnìkejì rẹ̀ sí rere, láti gbé e ró.
Kila omo wetu asogwaje upalamani wakwe hweli ega minza, hwidala lya hulengange.
3 Nítorí Kristi pàápàá kò ṣe ohun tí ó wu ara rẹ̀, ṣùgbọ́n bí a ti kọ ọ́ pé, “Ẹ̀gàn àwọn ẹni tí ń gàn ọ́ ṣubú lù mi.”
Hata oyo Kilisiti saga ahwilolaga yuyo mwene. Hwa huje alinashi sagasimbilwe, “Esnundo zyabhala bhabhalijile ganajile nene.”
4 Nítorí ohun gbogbo tí a kọ tẹ́lẹ̀, ni a kọ láti fi kọ́ wa pé, nípa sùúrù àti ìtùnú ìwé mímọ́, kí àwa lè ní ìrètí.
Hwa hohonti hahatagaliye asimbwe, hasimbilwe hwutilogozye, hwa huje ashilile ajimbe naashilile apelwe umwoyo nendajizyo angatili nelyomi.
5 Kí Ọlọ́run, ẹni tí ń fún ni ní sùúrù àti ìtùnú fún yin láti ní inú kan sí ara yín gẹ́gẹ́ bí i Jesu Kristi,
Eshi Ongolobhe umwene wajimbe nawatipele omwoyo naabhapele abhe nensebho sawa nahwakila omo alengane nu Yesu uKilisti.
6 kí ẹ̀yin kí ó lè fi ọkàn kan àti ẹnu kan fi ògo fún Ọlọ́run, Baba Olúwa wa Jesu Kristi.
Awezizye abhombe eshi husebho emo muwezye humwinyile hwiilomu limo Ongolobhe nu baada hwa Gosi wetu uYesu Kilisti.
7 Nítorí náà ẹ gba ara yín mọ́ra, gẹ́gẹ́ bí Kristi ti gbà wá mọ́ra fún ògo Ọlọ́run.
Hweeli posheli kila oomo, nashishila uKilisti nabhaposheye, hwatafihwe hwa Ngolobhe.
8 Mo sì wí pé, a rán Kristi láti ṣe ìránṣẹ́ ìkọlà àwọn tí ṣe Júù nítorí òtítọ́ Ọlọ́run, láti fi ìdí àwọn ìlérí tí a ti ṣe fún àwọn baba múlẹ̀,
Huje eyanga huje uKilisti abhehwelwe tumwahwa tohala hwidala elilyoli hwa Ngolobhe. Abhombile eshi huje awezye abhonesye endajizyo zye zyafumile hwa madaada,
9 kí àwọn aláìkọlà kí ó lè yin Ọlọ́run lógo nítorí àánú rẹ̀; gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé: “Nítorí èyí ni èmi ó ṣe yìn ọ́ láàrín àwọn Kèfèrí, Èmi ó sì kọrin sí orúkọ rẹ.”
na hwa mataifa humwembele Ongolobhe hwuwenee yakwe. Nashi salyandihwe, hwa huje embafumwe esifa huliwe nalengane nabhe mataifa nahwembe esifa ashilile itawa lyakwe.”
10 Ó sì tún wí pé, “Ẹ̀yin Kèfèrí, ẹ ma yọ̀, pẹ̀lú àwọn ènìyàn rẹ̀.”
Nantele eyanga, “Shanji, amwee mubhatu bhemataifa, pandwemo na bhantu bhakwe.”
11 Àti pẹ̀lú, “Ẹyin Olúwa, gbogbo ẹ̀yin Kèfèrí; ẹ kọ orin ìyìn sí, ẹ̀yin ènìyàn gbogbo.”
Nantele, “Mtofyaje Ogosi, amwe mmataifa mwetileshi bhemataifa; goti bamwinulaje umwe.”
12 Isaiah sì tún wí pé, “Gbòǹgbò Jese kan ń bọ̀ wá, òun ni ẹni tí yóò dìde ṣe àkóso àwọn Kèfèrí; Àwọn Kèfèrí yóò ní ìrètí nínú rẹ̀.”
Nantele oIsaya ayanga, “Hwaibha izii elya Yese, na oomo aibhomba atabhale amwanya yemataifa. Amataifa bhaibha nulusobhelo ashilile omwene.”
13 Ǹjẹ́ kí Ọlọ́run ìrètí kí ó fi gbogbo ayọ̀ òun àlàáfíà kún yín bí ẹ̀yin ti gbà á gbọ́, kí ẹ̀yin kí ó lè pọ̀ ní ìrètí nípa agbára Ẹ̀mí Mímọ́.
Eshi Ongolobhe owe sobhezyo abhamemwe nashee hwoti nulweteho hwa mweteshele, huje muwezye ahojelele ashilile esobhezyo, hwidandi elya Ompepo Ofinjile.
14 Ẹ̀yin ará, èmi gan alára ti ní ìdánilójú, pé ẹ̀yin pàápàá kún fún oore, a sì fi gbogbo ìmọ̀ kún un yín, ẹ̀yin sì jáfáfá láti máa kọ́ ara yín.
Nene nimwene evutililwe namwe, mwaholo bhane. Evitulilwe namwe mmemile uwinza, mmemile enjele zyonti. Evutililwe huje amwe muwenza apelane kila oomo nuwamwabho.
15 Síbẹ̀ mo ti fi ìgboyà kọ̀wé sí yín lórí àwọn kókó-ọ̀rọ̀ kan, bí ẹni ti ń rán yín létí àwọn kókó-ọ̀rọ̀ náà, nítorí oore-ọ̀fẹ́ tí a ti fi fún mi láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run
Lakini ewandiha hwelyomi nsini hulimwi humwanya yemambo gagahweli huje ebhakomboshe nantele, husababu yeshipawa shepewilwe nu Ngolobhe.
16 láti jẹ́ ìránṣẹ́ Kristi Jesu láàrín àwọn Kèfèrí láti polongo ìyìnrere Ọlọ́run gẹ́gẹ́ bí ojúṣe àlùfáà, kí àwọn Kèfèrí lè jẹ́ ẹbọ ọrẹ ìtẹ́wọ́gbà fún Ọlọ́run, èyí tí a ti fi Ẹ̀mí Mímọ́ yà sí mímọ́.
Eshipawa eshishali huje embetumwa wa Yesu Kilisti watumwilwe hwa mataifa, ahwifumwe nashi oodimi we bhangili lya Ngolobhe. Nezagawezye abhombe eshi ahwifumwe hwane hwamataifa hubhe hukondelwe, nahubhehwelwe hu Ngolobhe hwidala lya Opepo Ofinjile.
17 Nítorí náà, mo ní ìṣògo nínú Kristi Jesu nínú iṣẹ́ ìránṣẹ́ mi fún Ọlọ́run.
Huje ashee hwane huli mwidala lya Kilisti nu Yesu nashilile hwa Ngolobhe.
18 Èmi kò sá à gbọdọ̀ sọ ohun kan bí kò ṣe èyí tí Kristi ti ọwọ́ mi ṣe, ní títọ́ àwọn Kèfèrí ṣọ́nà láti ṣe ìgbọ́ràn sí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run nípa ọ̀rọ̀ àti ìṣe mi,
Huje sembwezizye alombelele wala ayanje lyolyonti huje uKilisti andengenye ashilile hwane ahwishe hwa mataifa. Eega amambo gamalishe hwizuu nidala,
19 nípa agbára iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu, nípa agbára Ẹ̀mí Ọlọ́run, tó bẹ́ẹ̀ láti Jerusalẹmu àti yíkákiri, àní títí fi dé Illirikoni, mo ti polongo ìyìnrere Kristi ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́.
hwilyomi ololesyo wemagosi, nahwilyomi elya Ompepo Ufinjile. Eli lyali hufume hu Yelusalemu, na zyogolele ohutali nashi iliriko, ebwezye ahweje hwoze humalisho wibhangili lya Kilisti.
20 Ó jẹ́ èrò mi ní gbogbo ìgbà láti wàásù ìyìnrere Kristi ní ibi gbogbo tí wọn kò tí ì mọ̀ ọ́n, kí èmi kí ó má ṣe máa mọ àmọlé lórí ìpìlẹ̀ ẹlòmíràn.
Hwidala eli, esebhozyane elilumbelele ibhagili, lakini sepala uKilisti pamanyishe hwitawa, huje esiwezye azenje pamwanya yesingi gwa muntu owamwabho.
21 Ṣùgbọ́n, gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé: “Àwọn ẹni tí a kò tí ì sọ ọ̀rọ̀ rẹ̀ fún yóò rí i, àti àwọn tí kò tí ì gbọ́, òye yóò sì yé.”
Nashi sagasimbilwe: “Eebho hwamwene sebhali nalyolyoti lyamwene ahenzele bhaihulola, nabhala bhasagabhamwovwezye bhenzehumanye.”
22 Ìdí nìyìí tí ààyè fi há pẹ́ tó bẹ́ẹ̀ fún mi kí n tó tọ̀ yín wa.
Hweli naliezigwilwe marahaminji ahwenze mwenyu.
23 Ṣùgbọ́n báyìí tí kò tún sí ibòmíràn fún mi mọ́ láti ṣiṣẹ́ ní ẹkùn yìí, tí èmi sì ti ń pòǹgbẹ láti ọdún púpọ̀ sẹ́yìn láti bẹ́ yín wò,
Lakini esalezi, sendinesehemu yoyoti ashile amikoa egaa, naendiieziliha hwumaha minji ahweze hwulimwi.
24 mo gbèrò láti ṣe bẹ́ẹ̀ nígbà tí mo bá lọ sí Spania. Èmi yóò rí i yín ní ọ̀nà àjò mi, àti pé ẹ ó mú mi já ọ̀nà níbẹ̀ láti ọ̀dọ̀ yín lọ, lẹ́yìn tí mo bá gbádùn ẹgbẹ́ yín fún ìgbà díẹ̀.
Huje mara zyoti nkembale Hispania etegemela abhalole nkeshile, etwalwe hwidala lyane namwe, baada yasogwe akhale namwe humdaa.
25 Ṣùgbọ́n ní báyìí, mo ń lọ sí Jerusalẹmu láti sé ìránṣẹ́ fún àwọn ènìyàn mímọ́ níbẹ̀.
Lakini esalezi embala hu Yelusalemu abhalishe aumini.
26 Nítorí pé ó wu àwọn tí ó wà ní Makedonia àti Akaia láti kó owó jọ fún àwọn tálákà tí ó wà ní àárín àwọn ènìyàn mímọ́ ní Jerusalẹmu.
Maana bhasogwelwe abhantu bha hu Makedonia na bha hu Akaya abhombe osanguzi welyoli hwabhala bhabhasagali nahantu bhamobhamo mwaumini ohwo hu Yeslusalemu.
27 Pẹ̀lú ayọ̀ ni wọ́n ń ṣe èyí, nítorí wọ́n gbà wí pé, wọ́n jẹ́ ajigbèsè fún wọn. Nítorí bí ó bá ṣe pé a fi àwọn Kèfèrí ṣe alájọni nínú ohun ẹ̀mí wọn, ajigbèsè sì ni wọn láti fi ohun ti ara ta wọ́n lọ́rẹ.
Lyoli, lwalilugano lwabho, nalyoli bhalinebha madeni gabho. Maana nkashile amataifa bhashilikile ashilile amambo gabho age mpepo, bhanamadeni bhope natele nabhalishe evitu vyesagabhali navyo.
28 Nítorí náà, nígbà tí mo bá ti ṣe èyí tán, tí mo bá sì di èdìdì èso náà fún wọn tán, èmi yóò ti ọ̀dọ̀ yín lọ sí Spania.
Eshi, natele amalezyezye evi nabhene nayerane humandodo ega hwabhene, anenaibhala mwidala padwemo namwee ooho hu Hispania.
29 Mo sì mọ̀ pé nígbà tí mo bá dé ọ̀dọ̀ yín, èmi yóò wà ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìbùkún ìyìnrere Kristi.
Emenye huje, nantele nkenenze hulimwi, naihweza ekamilishe hwuwinji wa Kilisti.
30 Èmí rọ̀ yín, ẹ̀yin arákùnrin àti arábìnrin, nítorí Olúwa wa Jesu Kristi, àti nítorí ìfẹ́ Ẹ̀mí, kí ẹ̀yin kí ó kún mi láti bá mi làkàkà nínú àdúrà yín sí Ọlọ́run fún mi.
Esalezi embasunda, bhaholo, hwa Gosi wetu uYesu Kilisiti, nahwigane lya Umpepo, huje mubhe padwemo nane ashirile apute hwenyu hwa Ngolobhe hwa ajili yalini.
31 Kí a lè kó mi yọ kúrò lọ́wọ́ àwọn aláìgbàgbọ́ ní Judea àti kí iṣẹ́ ìránṣẹ́ tí mo ní sí Jerusalẹmu le jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà lọ́dọ̀ àwọn ènìyàn mímọ́ níbẹ̀,
Putaji huje epone afume hwa bhene bhasaga bhane nshinshi ashilile hu Yudea, na huje embombo yane ohwo hu Yelusalemu ewezye aposhelelwe nalokole.
32 kí èmi le fi ayọ̀ tọ̀ yín wa, nípa ìfẹ́ Ọlọ́run, àti kí èmi lè ní ìtura pọ̀ pẹ̀lú yín.
Putaji huje engenza hulimwi seshiye ashilile huwinza wa Ngolobhe, na huje embepadwemo namwe, embwezye antoye.
33 Kí Ọlọ́run àlàáfíà wà pẹ̀lú gbogbo yín. Àmín.
Nu Ngolobhe owewene abhe padwemo namwe mwentii. Amina.

< Romans 15 >