< Romans 13 >

1 Kí olúkúlùkù ọkàn kí ó foríbalẹ̀ fún àwọn aláṣẹ tí ó wà ní ipò gíga. Nítorí kò sí àṣẹ kan, bí kò ṣe láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá; àwọn aláṣẹ tí ó sì wà, láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run ni a ti lànà rẹ̀ wá.
Kila nafsi naibhe nahwishe hwa bhabhali pamwanya, hwahuje nomoo awemelelele hwahuje efumile hwa Ngolobhe. Ne mamlaka zyezihweli zibhehwelwe no Ngolobhe.
2 Nítorí ẹni tí ó bá tàpá sí àṣẹ, ó tàpá sí ìlànà Ọlọ́run; àwọn ẹni tí ó ba sì ń tàpá, yóò gba ẹ̀bi fún ara wọn.
Hwola waikhana emamlaka eyo akhana ndapizyo zya Ngolobhe; na bhala bhabhayikhana bhenzeyiposhele aloongwe humwanya yabho bhebho.
3 Nítorí àwọn ìjòyè kò wá láti dẹ́rùbà àwọn tí ń ṣe rere, bí kò ṣe àwọn tó ń ṣe búburú. Ǹjẹ́ ìwọ ha fẹ́ di òmìnira kúrò nínú ẹ̀rù ẹni tó wà ní ipò àṣẹ. Nítorí náà ṣe èyí tó ó dára, ìwọ yóò sì gba ìyìn láti ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Hwa huje alongozi sebhatisizya hwabhala bhabhabhomba aminza, huje hwabhala bhabhabhomba embibhi. Huje oziliha kutohwogope abhe mamlaka? Bhombaga gagali miza, na bhenze huntufyee hwego.
4 Nítorí ìránṣẹ́ Ọlọ́run ni i ṣe fún ọ́ sí rere. Ṣùgbọ́n bí ìwọ bá ń ṣé búburú, máa bẹ̀rù, nítorí kò gbé idà náà lásán. Nítorí ìránṣẹ́ Ọlọ́run ní í ṣe, olùgbẹ̀san láti ṣiṣẹ́ ìbínú lára ẹni tí ń ṣe búburú.
Hwa huje ulitumwa wa Ngolobhe waho hwaajili yemiza. Nkashile obhabhombe gagali mabhibhi, ogopa; hwa huje sagabeba ipanga bila sababu. Hwa huje ulitumwa wa Ngolobhe, owalipe eshisasi hwikuni humwanya yola wabhomba embibhi.
5 Nítorí náà, ẹ̀yin kò gbọdọ̀ má tẹríba fún àwọn aláṣẹ, kì í ṣe nítorí ti ìbínú nìkan, ṣùgbọ́n nítorí ẹ̀rí ọkàn pẹ̀lú.
Hwe lyo ohwaziwa ahwiyishe, sehwisababu yekuni, huje nahwe sababu yesebho.
6 Nítorí ìdí èyí, ẹ san owó òde pẹ̀lú, nítorí ìránṣẹ́ Ọlọ́run ni wọ́n, èyí náà ni wọ́n ń bojútó nígbà gbogbo.
Hwaajili yega olipa ekodi. Hwa huje bhebhali ne mamlaka bhatumwa bha Ngolobhe, ebho bhabha hwedelesha abhombe embombo ene.
7 Ẹ san ohun tí ó tọ́ fún ẹni gbogbo: owó òde fún ẹni tí owó òde í ṣe tirẹ̀: owó bodè fún ẹni tí owó bodè í ṣe tirẹ̀: ẹ̀rù fún ẹni tí ẹ̀rù í ṣe tirẹ̀; ọlá fún ẹni tí ọlá í ṣe tirẹ̀.
Bhapeli kila omo hala habhadayi: nkakodi hwu kodi; nkaushuli hwaziwa ushulu; nkawoga uwaziwa waaga; nkanshinshi ehwaziwa nshinshi.
8 Ẹ má ṣe jẹ ẹnikẹ́ni ní gbèsè ohun kan, bí kò ṣe pé kí a fẹ́ ọmọ ẹnìkejì ẹni, nítorí ẹni tí ó bá fẹ́ ọmọnìkejì rẹ̀, ó kó òfin já.
Mgajedaiwe no mutu ahantu hohoti, hahahwaziwa oluganano mwemwe hwa mwemwe. Hwa huje olawagene oparamani wakwe amalile ikalata.
9 Àwọn òfin, “Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe panṣágà,” “Ìwọ kò gbọdọ̀ pànìyàn,” “Ìwọ kò gbọdọ̀ jalè,” “Ìwọ kò gbọdọ̀ jẹ́rìí èké,” “Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe ojúkòkòrò,” bí òfin mìíràn bá sì wà, ni a papọ̀ ṣọ̀kan nínú òfin kan yìí: “Fẹ́ ẹnìkéjì rẹ gẹ́gẹ́ bí ara rẹ̀.”
Hwa huje, “Sagaobhabhombe umalaya, sagaobhagoje, sagaobhahwibhe, sagaobhazilishe,” na kashile ehweli endajizo eyamwabho yope, emanyishe ashilile eli: “Obhahugane oparamani waho nashi wewe umwene.”
10 Ìfẹ́ kì í ṣe ohun búburú sí ọmọnìkejì rẹ̀, nítorí náà ìfẹ́ ni àkójá òfin.
OLugano sagabhibhi hwa paramani hwa muntu. Hwelyo ulugano malishilo hwe nkalata.
11 Àti èyí, bí ẹ̀yin ti mọ àkókò pé, ó ti tó wákàtí nísinsin yìí fún yín láti jí lójú orun, nítorí nísinsin yìí ni ìgbàlà wa súnmọ́ etílé ju ìgbà tí àwa ti gbàgbọ́ lọ.
Hwu sababu yeli, mmenye uwakati, huje hufishile wakati wafume muntulo. Huje olokole wetu ufishile papepe nu wakati wula owelweteshelo olwewandilo.
12 Òru bù kọjá tan, ilẹ̀ sì fẹ́rẹ mọ́: nítorí náà ẹ jẹ́ kí a bọ́ ara iṣẹ́ òkùnkùn sílẹ̀, kí a sì gbé ìhámọ́ra ìmọ́lẹ̀ wọ̀.
Nusiku hwendeleye, nusanya upalamiye. Tibheshe ashenje amadala agenkisi, tikwate esilaha ezye lukhozyo.
13 Jẹ́ kí a má rin ìrìn títọ́, bí ní ọ̀sán; kì í ṣe ní ìréde òru àti ní ìmutípara, kì í ṣe ni ìwà èérí àti wọ̀bìà, kì í ṣe ní ìjà àti ìlara.
Nativalaje shinza shinza, nashi mlukhozyo saganashi eshikulukulu eshembibhi nashi akholwe. Natigajebhale humbibhi nashi azilishe saga ugawezya aimale, nashi ashilile uwivu ne jela.
14 Ṣùgbọ́n ẹ gbé Jesu Kristi Olúwa wọ̀, kí ẹ má sì pèsè fún ara, láti máa mú ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ rẹ̀ ṣẹ.
Huje tikwale Ogosi oYesu Kilisti, natiga jebheshe idala ashilile obele, huzilisyo zyakwe.

< Romans 13 >