< Revelation 1 >
1 Ìfihàn ti Jesu Kristi, tí Ọlọ́run fi fún un, láti fihàn fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, ohun tí kò le ṣàìṣẹ ní lọ́ọ́lọ́ọ́; ó sì ránṣẹ́, ó sì fi í hàn láti ọwọ́ angẹli rẹ̀ wá fún Johanu, ìránṣẹ́ rẹ̀,
Jézus Krisztus kinyilatkoztatása, amelyet Isten adott neki, hogy megmutassa szolgáinak mindazt, amiknek hamar meg kell történnie. Elküldve pedig ezt az ő angyala által, kijelentette szolgájának, Jánosnak,
2 ẹni tí ó jẹ́rìí ohun gbogbo tí ó rí, èyí ì ni ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, àti ẹ̀rí ti Jesu Kristi.
aki bizonyságot tett Isten beszédéről, mindenről, amit látott.
3 Ẹni ìbùkún ni ẹni tí ń kà, àti àwọn tí ó ń gbọ́ ọ̀rọ̀ ìsọtẹ́lẹ̀ yìí, tí ó sì ń pa nǹkan wọ̀n-ọn-nì tí a kọ sínú rẹ̀ mọ́, nítorí ìgbà kù sí dẹ̀dẹ̀.
Boldog, aki olvassa, és aki hallgatja ennek a próféciának igéit, és megtartja mindazt, amelyek meg vannak írva azokban, mert az idő közel van.
4 Johanu, Sí àwọn ìjọ méje tí ń bẹ ní Asia: Oore-ọ̀fẹ́ fún yín, àti àlàáfíà, láti ọ̀dọ̀ ẹni tí ó ń bẹ, tí ó sì ti wà, tí ó sì ń bọ̀ wá; àti láti ọ̀dọ̀ àwọn ẹ̀mí méje tí ń bẹ níwájú ìtẹ́ rẹ̀;
János a hét gyülekezetnek, amelyek Ázsiában vannak: Kegyelem és békesség attól, aki van, és aki volt, és aki eljövendő, és a hét lélektől, akik királyi széke előtt vannak,
5 àti láti ọ̀dọ̀ Jesu Kristi, ẹlẹ́rìí olóòtítọ́, àkọ́bí nínú àwọn òkú, àti aláṣẹ àwọn ọba ayé. Ẹni tí ó fẹ́ wa, ẹni tí ó gbà wá kúrò lọ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wa nípa ẹ̀jẹ̀ rẹ̀,
és Jézus Krisztustól, aki hű tanú, a halottak közül az elsőszülött, és a föld királyainak fejedelme: aki minket szeretett, és vére által megtisztított bűneinktől,
6 tí ó sì ti fi wá jẹ ọba àti àlùfáà láti sin Ọlọ́run àti Baba rẹ; tirẹ̀ ni ògo àti ìjọba láé àti láéláé. Àmín. (aiōn )
és az ő Istenének és Atyjának királyaivá és papjaivá tett minket: övé legyen a dicsőség és a hatalom mindörökké. Ámen. (aiōn )
7 “Kíyèsi i, o ń bọ̀ nínú àwọsánmọ̀, gbogbo ojú ni yóò sì rí i, àti àwọn tí ó gún un ní ọ̀kọ̀ pẹ̀lú”; àti gbogbo orílẹ̀-èdè ayé ni “yóò sì máa pohùnréré ẹkún nítorí rẹ̀.”
Íme, eljön a felhőkön, és minden szem meglátja őt, még azok is, akik átszegezték és siratja őt a földnek minden nemzetsége. Úgy van. Ámen.
8 “Èmi ni Alfa àti Omega,” ni Olúwa Ọlọ́run wí, “ẹni tí ó ń bẹ, tí ó ti wà, tí ó sì ń bọ̀ wá, alágbára.”
Én vagyok az Alfa és az Ómega, a Kezdet és a Vég, ezt mondja az Úr, aki van, aki volt, és aki eljövendő, a Mindenható.
9 Èmi, Johanu, arákùnrin yín àti alábápín pẹ̀lú yín nínú wàhálà àti ìjọba àti sùúrù tí ń bẹ nínú Jesu, wà ní erékúṣù tí a ń pè ní Patmo, nítorí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, àti nítorí ẹ̀rí Jesu Kristi.
Én, János, aki atyafiatok és társatok vagyok Jézus Krisztus szenvedésében és királyságában és tűrésében, a szigeten voltam, amit Patmosznak neveznek, Isten beszédéért és Jézus Krisztus bizonyságtételéért.
10 Mo wà nínú Ẹ̀mí ní ọjọ́ Olúwa, mo sì gbọ́ ohùn ńlá kan lẹ́yìn mi, bí ìró ìpè,
Lélekben elragadtattam az Úr napján, és a hátam mögött trombitához hasonló hangos szót hallottam,
11 Ó ń wí pé, “Kọ́ ìwé rẹ̀, ohun tí ìwọ rí, kí ó sí fi ránṣẹ́ sí àwọn ìjọ méje; sí Efesu, àti sí Smirna, àti sí Pargamu, àti sí Tiatira, àti sí Sardi, àti sí Filadelfia, àti sí Laodikea.”
amely ezt mondta: „Én vagyok az Alfa és az Ómega, az első és az utolsó. Amit látsz, írd meg egy könyvben és küldd el a hét gyülekezetnek, amelyek Ázsiában vannak: Efezusba, Szmirnába, Pergamonba, Thiatirába, Szárdiszba, Filadelfiába és Laodiceába“.
12 Mo sì yí padà láti wo ohùn tí ń bá mi sọ̀rọ̀. Nígbà tí mo yípadà, mo rí ọ̀pá fìtílà wúrà méje,
Megfordultam, hogy lássam ki szólt hozzám. Megfordulva hét arany gyertyatartót láttam,
13 àti láàrín àwọn ọ̀pá fìtílà náà, ẹnìkan tí ó dàbí “ọmọ ènìyàn,” tí a wọ̀ ní aṣọ tí ó kanlẹ̀ dé ẹsẹ̀, tí a sì fi àmùrè wúrà dì ní ẹ̀gbẹ́.
és a hét gyertyatartó között egy emberi lényhez hasonlót, aki bokáig érő hosszú ruhába volt öltözve, mellénél aranyövvel körülövezve.
14 Orí rẹ̀ àti irun rẹ̀ funfun bí ẹ̀gbọ̀n òwú, ó funfun bí yìnyín; ojú rẹ̀ sì dàbí, ọwọ́ iná.
Feje és haja fehér volt, mint a hófehér gyapjú, szeme pedig, mint a tűz lángja.
15 Ẹsẹ̀ rẹ̀ sì dàbí idẹ dáradára, bí ẹni pé a dà á nínú ìléru; ohùn rẹ̀ sì dàbí ìró omi púpọ̀.
Lába hasonló volt a kemencében izzó érchez, szava pedig, mint nagy vízesés zúgása.
16 Ó sì ní ìràwọ̀ méje ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀; àti láti ẹnu rẹ̀ wá ni idà olójú méjì mímú ti jáde. Ojú rẹ̀ sì dàbí oòrùn tí ó ń fi agbára rẹ̀ hàn.
Jobb kezében hét csillag volt, szájából kétélű éles kard jött ki, arca pedig olyan volt, mint a nap, amikor teljes erejével fénylik.
17 Nígbà tí mo rí i, mo wólẹ̀ ní ẹsẹ̀ rẹ̀ bí ẹni tí ó kú. Ó sì fi ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ lé mi, ó ń wí fún mi pé, “Má ṣe bẹ̀rù. Èmi ni ẹni ìṣáájú àti ẹni ìkẹyìn.
Amikor megláttam, lábához estem, mint egy halott. Ő rám tette jobb kezét, és ezt mondta: „Ne félj, én vagyok az első és utolsó,
18 Èmi ni ẹni tí ó ń bẹ láààyè, tí ó sì ti kú; sì kíyèsi i, èmi sì ń bẹ láààyè sí i títí láé! Mo sì ní kọ́kọ́rọ́ ikú àti ti ipò òkú lọ́wọ́. (aiōn , Hadēs )
és az Élő. Halott voltam, és íme, élek örökkön örökké. Ámen. Nálam vannak a pokolnak és a halálnak kulcsai. (aiōn , Hadēs )
19 “Kọ̀wé nítorí náà ohun tí ìwọ ti rí, àti ti ohun tí ń bẹ, àti ti ohun tí yóò hù lẹ́yìn èyí;
Írd meg, amiket láttál, amik vannak, és amik ezek után lesznek:
20 ohun ìjìnlẹ̀ tí ìràwọ̀ méje náà tí ìwọ rí ní ọwọ́ ọ̀tún mi, àti ọ̀pá wúrà fìtílà méje náà. Ìràwọ̀ méje ni àwọn angẹli ìjọ méje náà: àti ọ̀pá fìtílà méje náà ní àwọn ìjọ méje.
a hét csillag titkát, amelyet láttál az én jobb kezemben és a hét arany gyertyatartót. A hét csillag a hét gyülekezet angyala, a hét gyertyatartó pedig a hét gyülekezet.“