< Revelation 4 >

1 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí èmi wò, sì kíyèsi i, ìlẹ̀kùn kan ṣí sílẹ̀ ní ọ̀run, ohùn kìn-ín-ní tí mo gbọ́ bí ohùn ìpè tí ń bá mi sọ̀rọ̀, tí ó wí pé, “Gòkè wá níhìn-ín, èmi ó sì fi ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn èyí hàn ọ́.”
ⲁ̅ⲙⲛⲛⲥⲁⲛⲁⲓ ⲁⲓⲛⲁⲩ ⲉⲩⲣⲟ ⲉϥⲟⲩⲏⲛ ϩⲣⲁⲓ ϩⲛⲧⲡⲉ ⲁⲩⲱ ⲧϣⲟⲣⲡ ⲛⲥⲙⲏ ⲛⲧⲁⲓⲥⲱⲧⲙ ⲉⲣⲟⲥ ⲛⲑⲉ ⲛⲟⲩⲥⲁⲗⲡⲓⲅⲝ ⲉⲥϣⲁϫⲉ ⲛⲙⲙⲁⲓ ⲉⲥϫⲱ ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⲁⲙⲟⲩ ⲉϩⲣⲁⲓ ⲉⲡⲉⲓⲙⲁ ⲧⲁⲧⲥⲁⲃⲟⲕ ⲉⲛⲉⲧⲛⲁϣⲱⲡⲉ ⲙⲛⲛⲥⲁⲛⲁⲓ
2 Lójúkan náà, mo sì wà nínú Ẹ̀mí, sì kíyèsi i, a tẹ́ ìtẹ́ kan ní ọ̀run, ẹnìkan sì jókòó lórí ìtẹ́ náà.
ⲃ̅ⲛⲧⲉⲩⲛⲟⲩ ⲁⲓϣⲱⲡⲉ ϩⲙⲡⲉⲡⲛⲁ ⲁⲩⲱ ⲉⲓⲥϩⲏⲏⲧⲉ ⲛⲉⲩⲛⲟⲩⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⲕⲏ ⲉϩⲣⲁⲓ ϩⲛⲧⲡⲉ ⲉⲣⲉⲟⲩⲁ ϩⲙⲟⲟⲥ ϩⲓⲡⲉⲑⲣⲟⲛⲟⲥ
3 Ẹni tí ó sì jókòó náà dàbí òkúta jasperi àti kaneliani lójú. Ni àyíká ìtẹ́ náà ni òṣùmàrè kan wà tí ó dàbí òkúta emeradi lójú.
ⲅ̅ⲁⲩⲱ ⲡⲉⲧϩⲙⲟⲟⲥ ϩⲓⲡⲉⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⲉϥⲉⲓⲛⲉ ⲛⲑⲟⲣⲁⲥⲓⲥ ⲛⲟⲩⲱⲛⲉ ⲛⲓⲁⲥⲡⲓⲥ ⲁⲩⲱ ⲛⲥⲁⲣⲇⲓⲛⲟⲥ ⲉⲣⲉⲟⲩⲟⲉⲓⲛ ⲕⲱⲧⲉ ⲉⲡⲉⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⲉϥⲟ ⲙⲡⲉⲓⲛⲉ ⲛⲟⲩⲥⲁⲣⲇⲓⲟⲛ
4 Yí ìtẹ́ náà ká sì ni ìtẹ́ mẹ́rìnlélógún mìíràn; àti lórí àwọn ìtẹ́ náà mo rí àwọn àgbà mẹ́rìnlélógún jókòó, tí a wọ̀ ni aṣọ àlà; adé wúrà sì wà ni orí wọn.
ⲇ̅ⲁⲩⲱ ⲉⲣⲉϫⲟⲩⲧⲁϥⲧⲉ ⲛⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⲙⲡⲕⲱⲧⲉ ⲙⲡⲉⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⲉⲣⲉϩⲉⲛⲡⲣⲉⲥⲃⲩⲧⲉⲣⲟⲥ ϩⲙⲟⲟⲥ ϩⲓⲡϫⲟⲩⲧⲁϥⲧⲉ ⲛⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⲉⲩϭⲟⲟⲗⲉ ⲛϩⲉⲛϩⲟⲓⲧⲉ ⲛⲟⲩⲟⲃϣ̅ ⲉⲣⲉϩⲉⲛⲕⲗⲟⲙ ⲛⲛⲟⲩⲃ ϩⲓϫⲛⲛⲉⲩⲁⲡⲏⲩⲉ
5 Àti láti ibi ìtẹ́ náà ni ìró mọ̀nàmọ́ná àti ohùn àti àrá ti jáde wá: níwájú ìtẹ́ náà ni fìtílà iná méje sì ń tàn, èyí tí ń ṣe Ẹ̀mí méje ti Ọlọ́run.
ⲉ̅ⲁⲩⲱ ⲛⲉⲩⲛⲏⲩ ⲉⲃⲟⲗ ϩⲙⲡⲉⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⲛϭⲓϩⲉⲛⲃⲣⲏϭⲉ ⲙⲛϩⲉⲛⲥⲙⲏ ⲙⲛϩⲉⲛϩⲣⲟⲩⲃⲃⲁⲓ ⲉⲣⲉⲥⲁϣϥⲉ ⲛⲗⲁⲙⲡⲁⲥ ⲛⲕⲱϩⲧ ⲙⲟⲩϩ ⲙⲡⲙⲧⲟ ⲉⲃⲟⲗ ⲙⲡⲉⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⲉⲧⲉⲛⲁⲓ ⲛⲉ ⲡⲥⲁϣϥ ⲙⲡ̅ⲛ̅ⲁ̅ ⲛⲧⲉⲡⲛⲟⲩⲧⲉ
6 Àti láti ibi ìtẹ́ náà ni òkun bi dígí wà tí o dàbí kristali. Àti yí ìtẹ́ náà ká ní ẹ̀gbẹ́ kọ̀ọ̀kan ni ẹ̀dá alààyè mẹ́rin tí ó kún fún ojú níwájú àti lẹ́yìn wọn.
ⲋ̅ⲁⲩⲱ ⲙⲡⲙⲧⲟ ⲉⲃⲟⲗ ⲙⲡⲉⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⲛⲉⲟⲩⲛⲟⲩⲑⲁⲗⲗⲁⲥⲥⲁ ⲛⲁⲃⲁϭⲏⲉⲓⲛ ⲉⲥⲉⲓⲛⲉ ⲛⲟⲩⲕⲣⲩⲥⲧⲁⲗⲟⲥ ⲁⲩⲱ ⲛⲧⲙⲏⲏⲧⲉ ⲙⲡⲉⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⲙⲛⲡⲉϥⲕⲱⲧⲉ ⲛⲉⲩⲛϥⲧⲟⲟⲩ ⲛⲍⲱⲟⲛ ⲉⲩⲙⲉϩ ⲛⲃⲁⲗ ϩⲓⲑⲏ ⲁⲩⲱ ϩⲓⲡⲁϩⲟⲩ
7 Ẹ̀dá kìn-ín-ní sì dàbí kìnnìún, ẹ̀dá kejì si dàbí ọmọ màlúù, ẹ̀dá kẹta sì ni ojú bi ti ènìyàn, ẹ̀dá kẹrin sì dàbí idì tí ń fò.
ⲍ̅ⲡϣⲟⲣⲡ ⲛⲍⲱⲟⲛ ⲉϥⲉⲓⲛⲉ ⲛⲟⲩⲙⲟⲩⲓ ⲡⲙⲉϩⲥⲛⲁⲩ ⲛⲍⲱⲟⲛ ⲉϥⲉⲓⲛⲉ ⲛⲟⲩⲙⲁⲥⲉ ⲡⲙⲉϩϣⲟⲙⲛⲧ ⲛⲍⲱⲟⲛ ⲉϥⲟ ⲛⲑⲉ ⲛϩⲟ ⲛⲣⲱⲙⲉ ⲡⲙⲉϩϥⲧⲟⲟⲩ ⲛⲍⲱⲟⲛ ⲉϥⲉⲓⲛⲉ ⲛⲟⲩⲁⲓⲧⲟⲥ ⲉϥϩⲏⲗ
8 Àwọn ẹ̀dá alààyè mẹ́rin náà, tí olúkúlùkù wọn ni ìyẹ́ mẹ́fà, kún fún ojú yíká ara àti nínú; wọn kò sì sinmi lọ́sàn àti lóru, láti wí pé:
ⲏ̅ⲁⲩⲱ ⲡⲉϥⲧⲟⲟⲩ ⲛⲍⲱⲟⲛ ⲛⲉⲧⲉⲡⲟⲩⲁ ⲡⲟⲩⲁ ⲙⲙⲟⲟⲩ ⲥⲟⲟⲩ ⲛⲧⲛϩ ϫⲓⲛⲛⲉⲩⲉⲓⲃ ⲙⲡⲉⲩⲕⲱⲧⲉ ⲉⲩⲙⲉϩ ⲛⲃⲁⲗ ⲙⲡⲉⲩϩⲟⲩⲛ ⲁⲩⲱ ⲙⲉⲩⲕⲁⲧⲟⲟⲧⲟⲩ ⲉⲃⲟⲗ ⲙⲡⲉϩⲟⲟⲩ ⲙⲛⲧⲉⲩϣⲏ ⲉⲩϫⲱ ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ϥⲟⲩⲁⲁ̅ⲃ ϥⲟⲩⲁ̅ⲃ ϥⲟⲩⲁⲁ̅ⲃ ⲡϫⲟⲉⲓⲥ ⲡⲛⲟⲩⲧⲉ ⲡⲡⲁⲛⲧⲱⲕⲣⲁⲧⲱⲣ ⲡⲉⲧϣⲟⲟⲡ ⲁⲩⲱ ⲡⲉⲧⲉⲛⲉϥϣⲟⲟⲡ ⲡⲉⲧⲛⲏⲩ
9 Nígbà tí àwọn ẹ̀dá alààyè náà bá sì fi ògo àti ọlá, àti ọpẹ́ fún ẹni tí o jókòó lórí ìtẹ́, tí o ń bẹ láààyè láé àti láéláé. (aiōn g165)
ⲑ̅ⲁⲩⲱ ⲉⲣϣⲁⲛⲛⲍⲱⲟⲛ ϯ ⲙⲡⲉⲟⲟⲩ ⲙⲛⲡⲧⲁⲓⲟ ⲙⲛⲧⲉⲩⲭⲁⲣⲓⲥϯⲁ ⲙⲡⲉⲧϩⲙⲟⲟⲥ ⲉϫⲙⲡⲉⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⲉⲧⲟⲛϩ ϣⲁⲛⲓⲉⲛⲉϩ (aiōn g165)
10 Àwọn àgbà mẹ́rìnlélógún náà yóò sì wólẹ̀ níwájú ẹni tí o jókòó lórí ìtẹ́, wọn yóò sì tẹríba fún ẹni tí ń bẹ láààyè láé àti láéláé, wọn yóò sì fi adé wọn lélẹ̀ níwájú ìtẹ́ náà, wí pé: (aiōn g165)
ⲓ̅ϣⲁⲩⲡⲁϩⲧⲟⲩ ⲛϭⲓⲡϫⲟⲩⲧⲁϥⲧⲉ ⲙⲡⲣⲉⲥⲃⲩⲧⲉⲣⲟⲥ ⲙⲡⲙⲧⲟ ⲉⲃⲟⲗ ⲙⲡⲉⲧϩⲙⲟⲟⲥ ϩⲓⲡⲉⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⲛⲥⲉⲟⲩⲱϣⲧ ⲙⲡⲉⲧⲟⲛϩ ϣⲁⲛⲓⲉⲛⲉϩ ⲛⲉⲛⲉϩ ⲁⲩⲱ ⲛⲥⲉⲛⲟⲩϫ ⲛⲛⲉⲩⲕⲗⲟⲙ ⲙⲡⲙⲧⲟ ⲉⲃⲟⲗ ⲙⲡⲉⲧϩⲙⲟⲟⲥ ϩⲓⲡⲉⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⲉⲩϫⲱ ⲙⲙⲟⲥ (aiōn g165)
11 “Olúwa àti Ọlọ́run, ìwọ ni o yẹ, láti gba ògo àti ọlá àti agbára, nítorí pé ìwọ ni o dá ohun gbogbo, àti nítorí ìfẹ́ inú rẹ̀ ni wọn fi wà tí a sì dá wọn.”
ⲓ̅ⲁ̅ϫⲉ ⲕⲙⲡϣⲁ ⲡϫ̅ⲥ̅ ⲡⲉⲛⲛⲟⲩⲧⲉ ⲛϫⲓ ⲙⲡⲉⲟⲟⲩ ⲙⲛⲡⲧⲁⲓⲟ ⲙⲛⲧϭⲟⲙ ϫⲉ ⲛⲧⲟⲕ ⲁⲕⲥⲛⲧⲛⲕⲁ ⲛⲓⲙ ⲁⲩⲱ ⲉⲩϣⲟⲟⲡ ⲁⲩⲱ ⲛⲧⲁⲩⲥⲱⲛⲧ ⲉⲧⲃⲉⲡⲉⲕⲟⲩⲱϣ

< Revelation 4 >