< Revelation 3 >

1 “Àti sí angẹli ìjọ ni Sardi kọ̀wé: Ọ̀rọ̀ wọ̀nyí ni ẹni tí ó ni Ẹ̀mí méje Ọlọ́run, àti ìràwọ̀ méje wí pé. Èmi mọ iṣẹ́ rẹ̀, àti pé ìwọ ní orúkọ pé ìwọ ń bẹ láààyè, ṣùgbọ́n ìwọ ti kú.
Tuhituhi atu hoki ki te anahera o te hahi i Harariha; Ko nga kupu ana, kei a ia nei nga Wairua e whitu o te Atua, me nga whetu e whitu; Ka matau ahau ki au mahi, na he ingoa tou, e ora ana koe, heoi he tupapaku ano koe.
2 Jí, kí o sì fi ẹsẹ̀ ohun tí ó kù múlẹ̀, tàbí tí ó ṣetán láti kú, nítorí èmi kò rí iṣẹ́ rẹ ni pípé níwájú Ọlọ́run.
Kia mataara, whakaukia nga mea e toe nei, ka tata nei te mate; kahore hoki ahau i kite i au mahi kia tino rite ki te aroaro o toku Atua.
3 Nítorí náà rántí bí ìwọ ti gbà, àti bí ìwọ ti gbọ́, kí o sì pa á mọ́, kí o sì ronúpìwàdà. Ǹjẹ́, bí ìwọ kò ba ṣọ́ra, èmi yóò dé sí ọ bí olè, ìwọ kì yóò sì mọ́ wákàtí tí èmi yóò dé sí ọ.
Kia mahara ra ki te rironga o nga mea i a koe, ki au i rongo ai, a puritia, ripeneta hoki. Na ki te kore koe e mataara, ka tae atu ahau ki a koe, ano he tahae; e kore hoki koe e matau ki te haora e tae atu ai ahau ki a koe.
4 Ìwọ ní orúkọ díẹ̀ ní Sardi, tí kò fi aṣọ wọn yí èérí; wọn yóò sì máa ba mi rìn ní aṣọ funfun: nítorí wọ́n yẹ.
Tena ano kei a koe etahi ingoa ouou nei i Harariha, kahore nei i poke o ratou kakahu; ka haereere tahi ena me ahau, he ma nga kakahu; no te mea he pai ratou.
5 Ẹni tí ó bá ṣẹ́gun, òun náà ni a ó fi aṣọ funfun wọ̀; èmi kì yóò pa orúkọ rẹ̀ kúrò nínú ìwé ìyè, ṣùgbọ́n èmi yóò jẹ́wọ́ orúkọ rẹ̀ níwájú Baba mi, àti níwájú àwọn angẹli rẹ̀.
Ko te tangata i a ia te wikitoria, ka whakakakahuria ia ki te kakahu ma; e kore ano hoki e ukuia e ahau tona ingoa i te pukapuka o te ora, a ka whakaaetia e ahau tona ingoa ki te aroaro o toku Matua, ki te aroaro ano hoki o ana anahera.
6 Ẹni tí ó ba létí, kí ó gbọ́ ohun tí Ẹ̀mí ń sọ fún àwọn ìjọ.
Ko te tangata he taringa tona, kia rongo ia ki ta te Wairua e mea nei ki nga hahi.
7 “Àti sí angẹli Ìjọ ni Filadelfia kọ̀wé. Ọ̀rọ̀ wọ̀nyí ni ẹni tí ó jẹ́ mímọ́ náà wí, ẹni tí ó ṣe olóòtítọ́, ẹni tí ó ní kọ́kọ́rọ́ Dafidi, ẹni tí ó ṣí, tí kò sí ẹni tí yóò tì; ẹni tí o sì tì, tí kò sì ẹni tí yóò ṣí i.
Tuhituhi atu hoki ki te anahera o te hahi i Pirarerepia; Ko nga kupu enei a te tapu, a te pono, kei a ia nei te ki o Rawiri, ko ia hei whakapuare, a kahore tetahi hei tutaki; mana hoki e tutaki a kahore tetahi hei whakapuare;
8 Èmi mọ iṣẹ́ rẹ̀, kíyèsi i, mo gbe ìlẹ̀kùn tí ó ṣí kálẹ̀ níwájú rẹ̀, tí kò sí ẹni tí o lè tì í; pé ìwọ ni agbára díẹ̀, ìwọ sì pa ọ̀rọ̀ mi mọ́, ìwọ kò sì sẹ́ orúkọ mi.
E matau ana ahau ki au mahi: na, kua hoatu e ahau ki tou aroaro he tatau puare, e kore nei e taea te tutaki e tetahi: he kaha hoki tou, he mea iti nei, kua puritia ano e koe taku kupu, kahore ano hoki koe i whakakahore ki toku ingoa.
9 Kíyèsi i, èmi ó mú àwọn ti Sinagọgu Satani, àwọn tí wọ́n ń wí pé Júù ni àwọn, tí wọn kì í sì ṣe bẹ́ẹ̀, ṣùgbọ́n tí wọn ń ṣèké; kíyèsi i, èmi ó mú kí wọn wá wólẹ̀ níwájú ẹsẹ̀ rẹ̀, kí wọn sì mọ̀ pé èmi tí fẹ́ ọ.
Na, maku e mea te hunga o te whakamenenga a Hatana, e mea nei he Hurai ratou, a ehara, he teka hoki na ratou; na, maku ratou e mea kia haere mai, kia koropiko ki mua i ou waewae, a kia matau kua arohaina koe e ahau.
10 Nítorí tí ìwọ tí pa ọ̀rọ̀ sùúrù mi mọ́, èmi pẹ̀lú yóò pa ọ́ mọ́ kúrò nínú wákàtí ìdánwò, tí ń bọ̀ wá dé bá gbogbo ayé, láti dán àwọn tí ń gbé orí ilẹ̀ ayé wò.
No te mea kua puritia e koe te kupu o taku manawanui, waihoki ka puritia koe e ahau i te haora o te whakamatautauranga, i taua haora meake nei puta ki te ao katoa, hei whakamatautau i te hunga e noho ana i te whenua.
11 Kíyèsi i, èmi ń bọ̀ kánkán, di èyí ti ìwọ ní mú ṣinṣin, kí ẹnikẹ́ni má ṣe gba adé rẹ.
Ka hohoro toku haere atu: kia mau ki tau, kei tangohia tou karauna e tetahi.
12 Ẹni tí ó ba ṣẹ́gun, òun ni èmi ó fi ṣe ọ̀wọ́n nínú tẹmpili Ọlọ́run mi, òun kì yóò sì jáde kúrò níbẹ̀ mọ́, èmi ó sì kọ orúkọ Ọlọ́run mi sí i lára, àti orúkọ ìlú Ọlọ́run mi, tí i ṣe Jerusalẹmu tuntun, tí ó ń ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run mi wá: àti orúkọ tuntun ti èmi tìkára mi.
Ko te tangata i a ia te wikitoria, maku ia e mea hei pou i roto i te whare o toku Atua, a e kore ia e haere atu i kona ki waho a muri atu; maku hoki e tuhituhi ki runga ki a ia te ingoa o toku Atua, te ingoa hoki o te pa o toku Atua, o Hiruharam a hou, ka heke iho nei i te rangi i toku Atua, me toku ingoa hou ano hoki.
13 Ẹni tí ó bá ní etí, kí ó gbọ́ ohun ti Ẹ̀mí ń sọ fún àwọn ìjọ.
Ko te tangata he taringa tona, kia rongo ia ki ta te Wairua e mea nei ki nga hahi.
14 “Àti sí angẹli ìjọ ní Laodikea kọ̀wé. Ọ̀rọ̀ wọ̀nyí ni ẹni tí ń jẹ́ Àmín wí, ẹlẹ́rìí olódodo àti olóòtítọ́, olórí ìṣẹ̀dá Ọlọ́run.
Tuhituhi atu hoki ki te anahera o te hahi i Raorikia; Ko nga kupu enei a te Amine, a te kaiwhakaatu pono, tika, a te timatanga o ta te Atua hanganga;
15 Èmi mọ̀ iṣẹ́ rẹ, pé ìwọ kò gbóná bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò tútù: èmi ìbá fẹ́ pé kí ìwọ kúkú tutù, tàbí kí ìwọ kúkú gbóná.
E matau ana ahau ki au mahi, ehara koe i te matao, ehara koe i te wera: ka pai ahau me i matao koe, me i wera ranei.
16 Ǹjẹ́ nítorí tí ìwọ lọ wọ́ọ́rọ́, tí o kò si gbóná, bẹ́ẹ̀ ni tí o kò tutù, èmi yóò pọ̀ ọ́ jáde kúrò ni ẹnu mi.
Heoi, i te mea he mahanahana kau koe, ehara i te matao, ehara i te wera, ka ruakina atu koe e ahau i roto i toku mangai.
17 Nítorí tí ìwọ wí pé, èmi ní ọrọ̀, èmi sì ń pọ̀ sí i ni ọrọ̀, èmi kò sì ṣe aláìní ohunkóhun; tí ìwọ kò sì mọ̀ pé, òsì ni ìwọ, ẹni-ìkáàánú, tálákà, afọ́jú, àti ẹni ìhòhò:
No te mea e ki ana koe, Kua whai taonga ahau, kua tini aku rawa, kahore hoki tetahi mea e matea ana e ahau; kahore hoki e matau he waikorohuhu noa iho koe, he he noa iho, he rawakore, he matapo, he mea kakahukore:
18 Èmi fún ọ ni ìmọ̀ràn pé kí o ra wúrà lọ́wọ́ mi tí a ti dà nínú iná, kí ìwọ lè di ọlọ́rọ̀; àti aṣọ funfun, kí ìwọ lè fi wọ ara rẹ̀, àti kí ìtìjú ìhòhò rẹ̀ má ba hàn kí ìwọ sì fi ohun ìkunra kun ojú rẹ̀, kí ìwọ lè ríran.
Ko taku kupu tenei ki a koe, kia hokona e koe i ahau he koura kua oti te tahu ki te ahi, kia whai rawa ai koe; he kakahu ma hoki, hei kakahu ki a koe, kia kaua ai e kitea te whakama o tou tunga kautanga; he rongoa hoki hei pani ki ou kanohi, kia kite ai koe.
19 Gbogbo àwọn ti èmi bá fẹ́ ni èmi ń bá wí, tí mo sì ń nà: nítorí náà, ní ìtara, kì ìwọ sì ronúpìwàdà.
Ko aku e aroha nei, ka riria e ahau, ka whiua; na, kia ngakau nui koe, ripeneta hoki.
20 Kíyèsi i, èmi dúró ni ẹnu ìlẹ̀kùn, èmi sì ń kànkùn, bí ẹnikẹ́ni bá gbọ́ ohun mi, tí ó sì ṣí ìlẹ̀kùn, èmi yóò sì wọlé tọ̀ ọ́ wá, èmi yóò sì máa bá a jẹun, àti òun pẹ̀lú mi.
Na, tenei ahau te tu nei i te tatau, te patukituki nei: ki te whakarongo tetahi ki toku reo, a ka uaki i te tatau, ka tomo atu ahau ki a ia, hei hoa kai mona, ko ia hoki hei hoa kai moku.
21 Ẹni tí ó bá ṣẹ́gun ni èmi yóò fi fún láti jókòó pẹ̀lú mi lórí ìtẹ́ mi, bí èmi pẹ̀lú ti ṣẹ́gun, tí mo sì jókòó pẹ̀lú Baba mi lórí ìtẹ́ rẹ̀.
Ko te tangata i a ia te wikitoria, ka hoatu e ahau ki a ia kia noho ki toku taha ki runga ki toku torona, penei me ahau i ahau nei te wikitoria, kua noho ki te taha o toku Matua i runga i tona torona.
22 Ẹni tí ó bá létí, kí ó gbọ́ ohun tí Ẹ̀mí ń sọ fún àwọn ìjọ.”
Ko te tangata he taringa tona, kia rongo ia ki ta te Wairua e mea nei ki nga hahi.

< Revelation 3 >