< Revelation 22 +

1 Ó sì fi odò omi ìyè kan hàn mi, tí ó mọ́ bí kirisitali, tí ń tí ibi ìtẹ́ Ọlọ́run àti tí Ọ̀dọ́-Àgùntàn jáde wá,
KUHIKUHI mai la oia ia'u i ka muliwai o ka wai ola, a akaka e like me ke aniani, puka mai la ia mai ka nohoalii mai o ke Akua a o ke Keikihipa.
2 ní àárín ìgboro rẹ̀, àti níhà èkínní kejì odò náà, ni igi ìyè gbé wà, tí o máa ń so onírúurú èso méjìlá, a sì máa so èso rẹ̀ ni oṣooṣù ewé igi náà sí wà fún mímú àwọn orílẹ̀-èdè láradà.
A mawaena o kona alanui a ma kela kapa keia kapa o ka muliwai, o ka laau o ke ola, e hua ana i ka hua he umikumamalua ke ano, akahi malama, akahi hua ana. A o na lau o ka laau, oia ka mea e ola'i na lahuikanaka.
3 Ègún kì yóò sì ṣí mọ: ìtẹ́ Ọlọ́run àti tí Ọ̀dọ́-àgùntàn ni yóò sì máa wà níbẹ̀; àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ yóò sì máa sìn ín.
Aole loa he mea ino malaila; a aia maloko o ia wahi ka nohoalii o ke Akua a me ke Keikihipa, a e malama kana poe kauwa ia ia.
4 Wọ́n ó si máa rí ojú rẹ̀; orúkọ rẹ̀ yóò si máa wà ni iwájú orí wọn.
A e ike aku no lakou i kona maka; a aia hoi kona inoa ma ko lakou mau lae.
5 Òru kì yóò sí mọ́; wọn kò sì ní wa ìmọ́lẹ̀ fìtílà, tàbí ìmọ́lẹ̀ oòrùn; nítorí pé Olúwa Ọlọ́run ni yóò tan ìmọ́lẹ̀ fún wọn: wọn ó sì máa jẹ ọba láé àti láéláé. (aiōn g165)
Aole po malaila, aole hoi make kukui, a me ka malamalama o ka la; no ka mea, na ka Haku na ke Akua no e hoomalamalama ia lakou: a e lilo lakou i mau alii a i ke ao pau ole. (aiōn g165)
6 Ó sì wí fún mi pé, “Òdodo àti òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ wọ̀nyí: Olúwa Ọlọ́run ẹ̀mí àwọn wòlíì ni ó sì ran angẹli rẹ̀ láti fi ohun tí ó ní láti ṣẹlẹ̀ láìpẹ́ yìí hàn àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀.”
I mai la kela ia'u, Ua pololei keia mau olelo, ua oiaio: a o ka Haku o ke Akua o ka poe kaula hemolele, hoouna mai la oia i kona anela, e hai mai i kana poe kauwa i na mea e hana koke ia mai.
7 “Kíyèsi i, èmi ń bọ̀ kánkán! Ìbùkún ni fún ẹni tí ń pa ọ̀rọ̀ ìsọtẹ́lẹ̀ inú ìwé yìí mọ́!”
Eia hoi, e hele koke mai no au, pomaikai ka mea malama i na olelo o ka wanana o keia buke.
8 Èmi, Johanu, ni ẹni tí ó gbọ́ tí ó sì ri nǹkan wọ̀nyí. Nígbà tí mo sì gbọ́ tí mo sì rí, mo wólẹ̀ láti foríbalẹ̀ níwájú ẹsẹ̀ angẹli náà, tí o fi nǹkan wọ̀nyí hàn mi.
Owau, o Ioane nei ka mea i ike a i lohe hoi i neia mau mea: a i ka wa a'u i lohe ai a ike aku ai hoi, moe iho la au e hoomana aku ma na wawae o ka anela nana i hoike mai ia'u i neia mau mea.
9 Nígbà náà ni ó wí fún mi pé, “Wó ò, má ṣe bẹ́ẹ̀, ìránṣẹ́ ẹlẹgbẹ́ rẹ ni èmi, àti ti àwọn arákùnrin rẹ̀ wòlíì, àti ti àwọn tí ń pa ọ̀rọ̀ inú ìwé yìí mọ́. Foríbalẹ̀ fún Ọlọ́run!”
I mai la kela ia'u, Uoki kau: no ka mea, owau no kou hoakauwa, kekahi o na kaula, kou mau hoahanau, ka poe e malama i na olelo o keia buke. E hoomana i ke Akua.
10 Ó sì wí fún mi pé, “Má ṣe fi èdìdì di ọ̀rọ̀ ìsọtẹ́lẹ̀ tí inú ìwé yìí, nítorí ìgbà kù sí dẹ̀dẹ̀.
I mai la kela ia'u, Mai hoopaa i ka wepa i na olelo o ka wanana o keia buke; no ka mea, ua kokoke mai ka manawa.
11 Ẹni tí ń ṣe aláìṣòótọ́, kí ó máa ṣe aláìṣòótọ́ nì só; àti ẹni tí ń ṣe ẹlẹ́gbin, kí ó máa ṣe ẹ̀gbin nì só; àti ẹni tí ń ṣe olódodo, kí ó máa ṣe òdodo nì só; àti ẹni tí ń ṣe mímọ́, kí ó máa ṣe mímọ́ nì só.”
O ka mea hewa, e mau no kona hewa; a o ka mea paumaele, e mau no kona paumaele; a o ka mea pono, o mau no kona pono; a o ka mea hemolele, e mau no kona hemolele.
12 “Kíyèsi i, èmi ń bọ̀ kánkán; èrè mí sì ń bẹ pẹ̀lú mi, láti sán fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀ yóò tí rí.
Eia hoi, e hele koke mai au, a eia no ia'u ka'u uku, a e haawi aku au i kela mea a i keia mea e like me kana hana ana.
13 Èmi ni Alfa àti Omega, ẹni ìṣáájú àti ẹni ìkẹyìn, ìpilẹ̀ṣẹ̀ àti òpin.
Owau no ka Alepa a me ka Omega, ke kumu a me ka welau, ka mua a me ka hope.
14 “Ìbùkún ni fún àwọn ti ń fọ aṣọ wọn, kí wọ́n lè ni ẹ̀tọ́ láti wá sí ibi igi ìyè náà, àti kí wọ́n lè gbà àwọn ẹnu ibodè wọ inú ìlú náà.
Pomaikai ka poe malama i kona mau kanawai, i hiki ke loaa ia lakou ko ka laau o ke ola, i komo aku hoi ma na puka, iloko o ke kulanakanhale.
15 Nítorí ni òde ni àwọn ajá gbé wà, àti àwọn oṣó, àti àwọn àgbèrè, àti àwọn apànìyàn, àti àwọn abọ̀rìṣà, àti olúkúlùkù ẹni tí ó fẹ́ràn èké tí ó sì ń hùwà èké.
Aia mawaho na ilio, a me na mea hoopiopio, a me na moe kolohe, a me na pepehi kanaka, a me ka poe hoomanakii, a me ka poe a pau i makemake a hana aku hoi ma ka wahahee.
16 “Èmi, Jesu, ni ó rán angẹli mi láti jẹ́rìí nǹkan wọ̀nyí fún yin ní tí àwọn ìjọ. Èmi ni gbòǹgbò àti irú-ọmọ Dafidi, àti ìràwọ̀ òwúrọ̀ tí ń tàn.”
Owau, o Iesu, ua hoouna aku au i ko'u anela, e hoike aku ia oukou i keia mau mea ma na ekalesia. Owau no ke kumu a me ka mamo a Davida; owau no ka hokuao malamalama.
17 Ẹ̀mí àti ìyàwó wí pé, “Máa bọ!” Àti ẹni tí ó ń gbọ́ kí ó wí pé, “Máa bọ̀!” Àti ẹni tí òǹgbẹ ń gbẹ kí ó wá, àti ẹni tí o bá sì fẹ́, kí ó gba omi ìyè náà lọ́fẹ̀ẹ́.
Ke olelo mai nei ka Uhane a me ka wahine mare; E hele mai. A e olelo hoi ka mea lohe, E hele mai A o ka mea makewai la, e hele mai ia. A o ka mea makemake, e lawe wale ia i ka wai o ke ola.
18 Èmi kìlọ̀ fún olúkúlùkù ẹni tó ń gbọ́ ọ̀rọ̀ ìsọtẹ́lẹ̀ inú ìwé yìí pé, bí ẹnikẹ́ni ba fi kún wọn, Ọlọ́run yóò fi kún àwọn ìyọnu tí a kọ sínú ìwé yìí fún un.
Ke hoike aku nei au i ka poe a pau i lohe i ka olelo o ka wanana o keia buke, Ina e hookui mai kekahi i ka mea hou me keia mau olelo, na ke Akua no e hookui mai me ia kanaka, i na mea ino i palapalaia maloko o keia buke:
19 Bí ẹnikẹ́ni bá sì mú kúrò nínú ọ̀rọ̀ ìwé ìsọtẹ́lẹ̀ yìí, Ọlọ́run yóò sì mú ipa tirẹ̀ kúrò nínú ìwé ìyè, àti kúrò nínú ìlú mímọ́ náà, àti kúrò nínú àwọn ohun tí a kọ sínú ìwé yìí.
A ina e lawe aku kekahi i kekahi olelo o ka buke o keia wanana, na ke Akua no e lawe aku i kona kuleana mai loko aku o ka laau o ke ola, a mai loko aku o ke kulanakauhale hoano, a mai waena aku o na mea i palapalaia maloko o keia buke.
20 Ẹni tí ó jẹ́rìí nǹkan wọ̀nyí wí pé, “Nítòótọ́ èmi ń bọ̀ kánkán.” Àmín. Máa bọ̀, Jesu Olúwa!
Ke i mai nei ka mea nana i hoike mai i keia mau mea, E oiaio no, e hele koke mai no au. Amene. E hele mai oe, e ka Haku, e Iesu.
21 Oore-ọ̀fẹ́ Jesu Olúwa kí ó wà pẹ̀lú gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́. Àmín.
O ke aloha o ka Haku, o Iesu Kristo, me oukou a pau. Amene. KA HOPENA.

< Revelation 22 +