< Revelation 21 >

1 Mo sì rí ọ̀run tuntun kan àti ayé tuntun kan, nítorí pé ọ̀run ti ìṣáájú àti ayé ìṣáájú ti kọjá lọ; Òkun kò sì ṣí mọ́.
ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲟⲩⲫⲉ ⳿ⲙⲃⲉⲣⲓ ⲛⲉⲙ ⲟⲩⲕⲁϩⲓ ⳿ⲙⲃⲉⲣⲓ ϯⲫⲉ ⲅⲁⲣ ⳿ⲛϩⲟⲩⲓϯ ⲛⲉⲙ ⲡⲓⲕⲁϩⲓ ⲁⲩϣⲉ ⲛⲱⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙⲙⲟⲛ ⲓⲟⲙ ϫⲉ.
2 Mo sì rí ìlú mímọ́, Jerusalẹmu tuntun ń ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ wá láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run, tí a ti múra sílẹ̀ bí ìyàwó tí a ṣe lọ́ṣọ̀ọ́ fún ọkọ rẹ̀.
ⲃ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓⲛⲁⲩ ⳿ⲉϯⲃⲁⲕⲓ ⲉⲑⲟⲩⲁⲃ ⳿ⲓⲗ̅ⲏ̅ⲙ̅ ⳿ⲙⲃⲉⲣⲓ ⲉⲥⲛⲏⲟⲩ ⳿ⲉⲡⲉⲥⲏⲧ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ϩⲓⲧⲉⲛ ⲫϯ ⲉⲥⲥⲉⲃⲧⲱⲧ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛⲟⲩϣⲉⲗⲉⲧ ⲉⲥⲥⲉⲗⲥⲱⲗ ⳿ⲙⲡⲉⲥϩⲁⲓ.
3 Mo sì gbọ́ ohùn ńlá kan láti orí ìtẹ́ náà wá, ń wí pé, “Kíyèsi i, àgọ́ Ọlọ́run wà pẹ̀lú àwọn ènìyàn, òun ó sì máa bá wọn gbé, wọn ó sì máa jẹ́ ènìyàn rẹ̀, àti Ọlọ́run tìkára rẹ̀ yóò wà pẹ̀lú wọn, yóò sì máa jẹ́ Ọlọ́run wọn.
ⲅ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲉⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛ⳿ⲥⲙⲏ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ⲉⲥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⲓⲥ ϯ ⳿ⲥⲕⲩⲛⲏ ⳿ⲛⲧⲉ ⲫϯ ⲉⲥⲭⲏ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲣⲱⲙⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲉϥ⳿ⲉϣⲱⲡⲓ ⲛⲉⲙⲱⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲑⲱⲟⲩ ϩⲱⲟⲩ ⲉⲩ⳿ⲉϣⲱⲡⲓ ⲛⲁϥ ⳿ⲉⲟⲩⲗⲁⲟⲥ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲑⲟϥ ⲫϯ ⲉϥ⳿ⲉϣⲱⲡⲓ ⲛⲉⲙⲱⲟⲩ.
4 Ọlọ́run yóò sì nu omijé gbogbo nù kúrò ni ojú wọn; kì yóò sì ṣí ikú mọ́, tàbí ọ̀fọ̀, tàbí ẹkún, bẹ́ẹ̀ ni kí yóò sí ìrora mọ́, nítorí pé ohun àtijọ́ tí kọjá lọ.”
ⲇ̅ⲉϥ⳿ⲉϥⲉⲧ ⲉⲣⲙⲏ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲛⲟⲩⲃⲁⲗ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲛⲉ ⲙⲟⲩ ϣⲱⲡⲓ ϫⲉ ⲟⲩⲇⲉ ϩⲏⲃⲓ ⲟⲩⲇⲉ ⳿ϧⲣⲱⲟⲩ ⳿ⲛⲛⲉ ϧⲓⲥⲓ ϣⲱⲡⲓ ϫⲉ ⲉⲡⲓⲇⲏ ⲛⲓϩⲟⲩⲁϯ ⲁⲩⲥⲓⲛⲓ ϩⲏⲡⲡⲉ ⲥⲉⲛⲁⲉⲣⲃⲉⲣⲓ ⲧⲏⲣⲟⲩ.
5 Ẹni tí ó jókòó lórí ìtẹ́ náà, sì wí pé, “Kíyèsi i, mo sọ ohun gbogbo di ọ̀tun!” Ó sì wí fún mi pé, “Kọ̀wé rẹ̀, nítorí ọ̀rọ̀ wọ̀nyí òdodo àti òtítọ́ ni wọ́n.”
ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉϫⲉ ⲫⲏⲉⲧϩⲉⲙⲥⲓ ϩⲓ ⲡⲓ⳿ⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⲛⲏⲓ ϫⲉ ϩⲏⲡⲡⲉ ϯⲛⲁⲁⲓⲧⲟⲩ ⳿ⲙⲃⲉⲣⲓ ⲧⲏⲣⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲏⲓ ϫⲉ ⳿ⲥϧⲁⲓ ⳿ⲛⲛⲁⲓⲥⲁϫⲓ ⲥⲉ⳿ⲛϩⲟⲧ ⲟⲩⲟϩ ϩⲁⲛⲙⲉⲑⲙⲏⲓ ⲛⲉ.
6 Ó sì wí fún mi pé, “Ó parí. Èmi ni Alfa àti Omega, ìpilẹ̀ṣẹ̀ àti òpin. Èmi ó sì fi omi fún ẹni tí òùngbẹ ń gbẹ láti inú orísun omi ìyè lọ́fẹ̀ẹ́.
ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲏⲓ ϫⲉ ⳿ⲁⲛⲟⲕ ⲡⲉ ⲡⲓⲁⲗⲁⲫⲁ ⲛⲉⲙ ⲡⲓⲱ ϯⲁⲣⲭⲏ ⲛⲉⲙ ⲡⲓϫⲱⲕ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲁⲛⲟⲕ ⲡⲉ ⲫⲏⲉⲑⲛⲁϯ ⳿ⲙⲫⲏⲉⲧⲟⲃⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ϯⲙⲟⲩⲙⲓ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ⳿ⲛⲱⲛϧ ⳿ⲛϫⲓⲛϫⲏ.
7 Ẹni tí ó ba ṣẹ́gun ni yóò jogún nǹkan wọ̀nyí; èmi ó sì máa jẹ́ Ọlọ́run rẹ̀, òun ó sì máa jẹ ọmọ mi.
ⲍ̅ⲫⲏⲉⲑⲛⲁϭⲣⲟ ⲉϥ⳿ⲉⲉⲣ⳿ⲕⲗⲏⲣⲟⲛⲟⲙⲓⲛ ⳿ⲛⲛⲁⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲓ⳿ⲉϣⲱⲡⲓ ⲛⲁϥ ⳿ⲛⲛⲟⲩϯ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲑⲟϥ ⲉϥ⳿ⲉϣⲱⲡⲓ ⲛⲏⲓ ⳿ⲛϣⲏⲣⲓ.
8 Ṣùgbọ́n àwọn ojo, àti aláìgbàgbọ́, àti ẹni ìríra, àti apànìyàn, àti àgbèrè, àti oṣó, àti abọ̀rìṣà, àti àwọn èké gbogbo, ni yóò ni ipa tiwọn nínú adágún tí ń fi iná àti sulfuru jó: èyí tí i ṣe ikú kejì.” (Limnē Pyr g3041 g4442)
ⲏ̅ⲛⲏ ⲇⲉ ⲉⲑⲛⲁⲉⲣ⳿ϣⲗⲁϩ ⳿ⲛϩⲏⲧ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲁⲧⲛⲁϩϯ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲥⲁϥϩⲏⲧ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲣⲉϥϧⲱⲧⲉⲃ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲡⲟⲣⲛⲟⲥ ⲛⲉⲙ ⲛⲓϣⲁⲙϣⲉ ⲓϧ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲥⲁⲙⲉⲑⲛⲟⲩϫ ⲡⲟⲩⲙⲉⲣⲟⲥ ⲉϥ⳿ⲉϣⲱⲡⲓ ϧⲉⲛ ϯⲗⲩⲙⲛⲏ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲓ⳿ⲭⲣⲱⲙ ⲛⲉⲙ ⲡⲓⲑⲏⲛ ⲉⲧⲉ ⲡⲓⲙⲟⲩ ⳿ⲙⲙⲁϩⲃ̅ ⲡⲉ. (Limnē Pyr g3041 g4442)
9 Ọ̀kan nínú àwọn angẹli méje, tí wọ́n ni ago méje, tí ó kún fún ìyọnu méje ìkẹyìn sì wá, ó sì ba mi sọ̀rọ̀ wí pé, “Wá níhìn-ín, èmi ó fi ìyàwó, aya Ọ̀dọ́-àgùntàn hàn ọ́.”
ⲑ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁϥ⳿ⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲟⲩⲁⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲡⲓⲍ̅ ⳿ⲛⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲛⲏⲉⲧⲉ ϯⲍ̅ ⳿ⲙⲫⲩⲁⲗⲏ ⳿ⲛⲧⲟⲧⲟⲩ ⲉⲩⲙⲉϩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲡⲓⲍ̅ ⳿ⲛⲉⲣϧⲟⲧ ⳿ⲛϧⲁ⳿ⲉ ⲁϥⲥⲁϫⲓ ⲛⲉⲙⲏⲓ ⲉϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⲁⲙⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲁⲧⲁⲙⲟⲕ ⳿ⲉϯϣⲉⲗⲉⲧ ⳿ⲧ⳿ⲥϩⲓⲙⲓ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲓϩⲓⲏⲃ.
10 Ó sì mu mi lọ nínú Ẹ̀mí si òkè ńlá kan tí o sì ga, ó sì fi ìlú náà hàn mi, Jerusalẹmu mímọ́, tí ń ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ wá láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run,
ⲓ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁϥⲟⲗⲧ ϧⲉⲛ ⲡⲓⲡ͞ⲛⲁ̅ ⳿ⲉ⳿ⲡϣⲱⲓ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛⲧⲱⲟⲩ ⲉϥϭⲟⲥⲓ ⲁϥⲧⲁⲙⲟⲓ ⳿ⲉϯⲃⲁⲕⲓ ⲉⲑⲟⲩⲁⲃ ⳿ⲓⲗ̅ⲏ̅ⲙ̅ ⲉⲥⲛⲏⲟⲩ ⳿ⲉⲡⲉⲥⲏⲧ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ϩⲓⲧⲉⲛ ⲫϯ.
11 tí ó ní ògo Ọlọ́run, ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ sì dàbí òkúta iyebíye gidigidi, àní bí òkúta jasperi, ó mọ́ bí kirisitali;
ⲓ̅ⲁ̅ⲑⲏ ⲉⲑⲟⲩⲁⲃ ⲉⲑⲙⲉϩ ⳿ⲛⲱⲟⲩ ⲡⲉⲥⲟⲩⲱⲓⲛⲓ ⲇⲉ ⲉϥⲟⲓ ⳿ⲛⲟⲩⲱⲓⲛⲓ ⲉϥⲧⲁⲓⲏⲟⲩⲧ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛⲟⲩⲟⲩⲱⲓⲛⲓ ⳿ⲛⲓⲁⲥⲡⲓⲥ ⲉϥⲧⲁⲓⲏⲟⲩⲧ ⲉϥⲟⲓ ⳿ⲛ⳿ⲭⲣⲓⲥⲧⲁⲗⲟⲥ.
12 Ó sì ní odi ńlá àti gíga, ó sì ni ẹnu ibodè méjìlá, àti ní àwọn ẹnu ibodè náà angẹli méjìlá àti orúkọ tí a kọ sára wọn tí i ṣe orúkọ àwọn ẹ̀yà méjìlá tí àwọn ọmọ Israẹli.
ⲓ̅ⲃ̅⳿ⲉⲟⲩⲟⲛ ⳿ⲛⲧⲁⲥ ⳿ⲛⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛⲥⲟⲃⲧ ⳿ⲙⲙⲁⲩ ⲉϥϭⲟⲥⲓ ⲛⲉⲙ ⲡⲓⲓ̅ⲃ̅ ⳿ⲙⲡⲩⲗⲱⲛ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓⲓ̅ⲃ̅ ⳿ⲛⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ϩⲓⲣⲉⲛ ⲛⲓⲡⲩⲗⲱⲛ ⲛⲉⲙ ϩⲁⲛⲣⲁⲛ ⲉⲩ⳿ⲥϧⲏⲟⲩⲧ ⳿ⲉ⳿ⲫⲣⲁⲛ ⳿ⲛϯⲓ̅ⲃ̅ ⳿ⲙⲫⲩⲗⲏ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲉⲛϣⲏⲣⲓ ⳿ⲙ⳿ⲡⲓⲥ̅ⲗ̅.
13 Ní ìhà ìlà-oòrùn ẹnu ibodè mẹ́ta; ní ìhà àríwá ẹnu ibodè mẹ́ta; ní ìhà gúúsù ẹnu ibodè mẹ́ta; àti ní ìhà ìwọ̀-oòrùn ẹnu ibodè mẹ́ta.
ⲓ̅ⲅ̅ⲥⲁ⳿ⲡⲉⲓⲉⲃⲧ ⲅ̅ ⳿ⲙⲡⲩⲗⲱⲛ ⲥⲁⲣⲏⲥ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲅ̅ ⳿ⲙⲡⲩⲗⲱⲛ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲡⲉⲙⲉⲛⲧ ⳿ⲛⲧⲉ ϯⲡⲟⲗⲓⲥ ⲅ̅ ⳿ⲙⲡⲩⲗⲱⲛ ⲟⲩⲟϩ ⲥⲁⲡⲉⲙϩⲓⲧ ⲅ̅ ⳿ⲙⲡⲩⲗⲱⲛ.
14 Odi ìlú náà sì ni ìpìlẹ̀ méjìlá, àti lórí wọn orúkọ àwọn Aposteli méjìlá tí Ọ̀dọ́-Àgùntàn.
ⲓ̅ⲇ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓⲥⲟⲃⲧ ⳿ⲛⲧⲉ ϯⲡⲟⲗⲓⲥ ⳿ⲉⲟⲩⲟⲛ ⲓ̅ⲃ̅ ⳿ⲛⲥⲉⲛϯ ⳿ⲙⲙⲟϥ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲩ⳿ⲥϧⲏⲟⲩⲧ ϩⲓⲱⲧⲟⲩ ⳿ⲛϫⲉ ⳿ⲫⲣⲁⲛ ⳿ⲙⲡⲓⲓ̅ⲃ̅ ⳿ⲛⲁⲡⲟⲥⲧⲟⲗⲟⲥ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲓϩⲓⲏⲃ.
15 Ẹni tí o sì ń bá mi sọ̀rọ̀ ní ọ̀pá-ìwọ̀n wúrà kan láti fi wọn ìlú náà àti àwọn ẹnu ibodè rẹ̀, àti odi rẹ̀.
ⲓ̅ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⲫⲏⲉⲧⲥⲁϫⲓ ⲛⲉⲙⲏⲓ ⳿ⲉⲟⲩⲟⲛ ⲟⲩⲕⲁϣ ⳿ⲛⲛⲟⲩⲃ ⳿ⲛⲧⲟⲧϥ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲉϥϣⲓ ⳿ⲛϯ ⲃⲁⲕⲓ ⲛⲉⲙ ⲛⲉⲥ⳿ϣⲑⲟⲙ ⲛⲉⲙ ⲛⲉⲥⲥⲟⲃⲧ.
16 Ìlú náà sì wà ní ibú mẹ́rin lọ́gbọọgba, gígùn rẹ̀ àti ìbú rẹ̀ sì dọ́gba: ó sì fi ọ̀pá-ìwọ̀n náà wọn ìlú náà wò, ó jẹ ẹgbàá mẹ́fà ibùsọ̀ gígùn rẹ̀ àti ìbú rẹ̀, àti gíga rẹ̀ sì dọ́gba.
ⲓ̅ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ϯⲃⲁⲕⲓ ⲛⲉ ⲟⲩⲧⲉⲧⲣⲁⲅⲱⲛⲟⲛ ⲧⲉ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛⲧⲉⲥϣⲓⲏ ⲡⲁⲓⲣⲏϯ ⲟⲛ ⲡⲉ ⲧⲉⲥⲟⲩⲏϣⲥⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥϣⲓ ⳿ⲛϯⲃⲁⲕⲓ ⲁϥϫⲉⲙⲥ ⲉⲥⲟⲓ ⳿ⲙⲓ̅ⲃ̅ ⳿ⲛϣⲟ ⳿ⲛ⳿ⲥⲧⲁⲇⲓⲟⲛ ⳿ⲛϣⲓⲏ ⲛⲉⲙ ⲧⲉⲥⲟⲩⲏ ϣⲥⲓ ⲛⲉⲙ ⲡⲉⲥϭⲓⲥⲓ ⲉⲩⲟⲓ ⳿ⲛⲟⲩϩⲩⲥⲟⲥ.
17 Ó sì wọn odi rẹ̀ ó jẹ́ ogóje ìgbọ̀nwọ́ lé mẹ́rin, gẹ́gẹ́ bí òsùwọ̀n ènìyàn, bẹ́ẹ̀ ni tí angẹli náà.
ⲓ̅ⲍ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩϣⲓ ⳿ⲙⲡⲉⲥⲥⲟⲃⲧ ⲁⲩϫⲉⲙϥ ⲉϥ⳿ⲓⲣⲓ ⳿ⲛⲣ̅ⲙ̅ⲇ̅ ⳿ⲛϣⲟ ⳿ⲡϣⲓ ⳿ⲛⲟⲩⲣⲱⲙⲓ ⲉⲧⲉ ⲫⲁ ⲟⲩⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲡⲉ.
18 A sì fi jasperi mọ odi ìlú náà. Ìlú náà sì jẹ́ kìkì wúrà, ó dàbí dígí tí o mọ́ kedere.
ⲓ̅ⲏ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲡⲕⲱϯ ⳿ⲙⲡⲓⲥⲟⲃⲧ ϯϩⲓⲟⲩ⳿ⲓ ⳿ⲛⲥⲉⲛϯ ⲛⲁⲥⲟⲓ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛⲟⲩⲓⲁⲥⲡⲓⲥ ⲡⲉ ⲟⲩⲟϩ ϯⲃⲁⲕⲓ ⲛⲁⲥⲟⲓ ⲡⲉ ⳿ⲛⲓⲉⲃ ⳿ⲛⲛⲟⲩⲃ ⲉϥⲟⲩⲁⲃ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛⲟⲩⲃⲁϫⲏⲓⲛⲓ ⲉϥⲟⲩⲁⲃ.
19 A fi onírúurú òkúta iyebíye ṣe ìpìlẹ̀ ògiri ìlú náà lọ́ṣọ̀ọ́. Ìpìlẹ̀ èkínní jẹ́ jasperi; èkejì, safiru; ẹ̀kẹta, kalkedoni; ẹ̀kẹrin, emeradi;
ⲓ̅ⲑ̅ⲟⲩⲟϩ ⲛⲓⲥⲉⲛϯ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲓⲥⲟⲃⲧ ⳿ⲛⲧⲉ ϯⲃⲁⲕⲓ ⲉⲩⲕⲏⲧ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲱⲛⲓ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲉⲧⲧⲁⲓⲏ ⲟⲩⲧ ϯⲥⲉⲛϯ ⳿ⲛϩⲟⲩⲓϯ ⲛⲉ ⲟⲩⲓⲁⲥⲡⲓⲥ ⲧⲉ ϯⲙⲁϩⲃ̅ϯ ⲟⲩⲥⲁⲡⲫⲓⲣⲟⲥ ⲧⲉ ϯⲙⲁϩⲅ̅ϯ ⲟⲩⲕⲁⲣⲭⲏ ⲇⲱⲛ ⲧⲉ ϯⲙⲁϩⲇ̅ ⲟⲩ⳿ⲥⲙⲁⲣⲁⲕⲇⲟⲥ.
20 ẹ̀karùnún, sardoniki; ẹ̀kẹfà, kaneliani; èkeje, krisoliti; ẹ̀kẹjọ, berili; ẹ̀kẹsànán, topasi; ẹ̀kẹwàá, krisoprasu; ẹ̀kọkànlá, jakiniti; èkejìlá, ametisiti.
ⲕ̅ϯⲙⲁϩⲉ̅ ⲟⲩⲥⲁⲣⲇⲟⲛⲓⲝ ϯⲙⲁϩⲋ̅ ⲟⲩⲥⲁⲣⲇⲓⲛⲟⲛ ϯⲙⲁϩⲍ̅ ⲟⲩ⳿ⲭⲣⲓⲥⲟⲗⲓⲛⲑⲟⲛⲥ ϯ ⲙⲁϩⲏ̅ ⲟⲩⲃⲩⲣⲓⲗⲗⲟⲥ ϯⲙⲁϩϧ̅ϯ ⲟⲩⲇⲟⲡⲁⲧⲓⲟⲛ ϯⲙⲁϩⲓ̅ϯ ⲟⲩϩⲩⲁⲕⲩⲛⲑⲓⲛⲟⲛ ϯⲙⲁϩⲓ̅ⲁ̅ ⲟⲩⲕⲩⲥⲟⲡⲁⲣⲁⲥⲟⲥ ϯⲙⲁϩⲓ̅ⲃ̅ ⲟⲩⲁⲙⲉⲑⲓⲧⲟⲥ.
21 Ẹnu ibodè méjèèjìlá jẹ́ perli méjìlá: olúkúlùkù ẹnu ibodè jẹ́ peali kan; ọ̀nà ìgboro ìlú náà sì jẹ́ kìkì wúrà, ó dàbí dígí dídán.
ⲕ̅ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓⲓ̅ⲃ̅ ⳿ⲙⲡⲩⲗⲱⲛ ⳿ⲙⲙⲁⲣⲅⲁⲣⲓⲧⲏ ⲥ ⳿ⲛⲟⲩⲁⲓ ⳿ⲛⲟⲩⲁⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓ⳿ϣⲑⲉϩ ⳿ⲛⲧⲉ ϯ ⲃⲁⲕⲓ ⲟⲩⲛⲟⲩⲃ ⲉϥⲟⲩⲁⲃ ⲡⲉ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛⲟⲩⲁⲃⲁϫⲏ ⲓⲛⲓ ⲉϥⲉⲣⲟⲩⲱⲓⲛⲓ.
22 Èmi kò sì ri tẹmpili nínú rẹ̀, nítorí pé Olúwa Ọlọ́run Olódùmarè ni tẹmpili rẹ̀, àti Ọ̀dọ́-àgùntàn.
ⲕ̅ⲃ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙⲡⲓⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲉⲣⲫⲉⲓ ⳿ⲛϧⲏⲧⲥ Ⲡ⳪ ⲅⲁⲣ ⲫϯ ⲡⲓⲡⲁⲛⲧⲟⲕⲣⲁⲧⲱⲣ ⲡⲉ ⲡⲉⲥⲉⲣⲫⲉⲓ ⲛⲉⲙ ⲡⲓϩⲓⲏⲃ.
23 Ìlú náà kò sì ní oòrùn, tàbí òṣùpá, láti máa tan ìmọ́lẹ̀ sí i, nítorí pé ògo Ọlọ́run ni ó ń tàn ìmọ́lẹ̀ sí i, Ọ̀dọ́-àgùntàn sì ni fìtílà rẹ̀.
ⲕ̅ⲅ̅ⲟⲩⲟϩ ϯⲃⲁⲕⲓ ⲛⲁⲥⲉⲣ⳿ⲛⲭⲣⲓⲁ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏ ⲁⲛ ⲡⲉ ⲟⲩⲇⲉ ⲡⲓⲓⲟϩ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲟⲩⲉⲣⲟⲩⲱⲓⲛⲓ ⳿ⲛϧⲏⲧⲥ ⳿ⲡⲱⲟⲩ ⲅⲁⲣ ⳿ⲙⲫϯ ⲁϥⲉⲣⲟⲩⲱⲓⲛⲓ ⳿ⲉⲣⲟⲥ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉⲥϧⲏⲃⲥ ⲡⲉ ⲡⲓϩⲓⲏⲃ.
24 Àwọn orílẹ̀-èdè yóò sì máa rìn nípa ìmọ́lẹ̀ rẹ̀, àwọn ọba ayé sì ń mú ògo wọn wá sínú rẹ̀.
ⲕ̅ⲇ̅ⲟⲩⲟϩ ⲉⲩ⳿ⲉⲙⲟϣⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲡⲉⲥⲟⲩⲱⲓⲛⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲓⲉⲑⲛⲟⲥ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲟⲩⲣⲱⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉ ⳿ⲡⲕⲁϩⲓ ⲉⲩ⳿ⲉ⳿ⲓⲛⲓ ⳿ⲙ⳿ⲡⲱⲟⲩ ⳿ⲛⲛⲓⲉⲑⲛⲟⲥ ⲛⲉⲙ ϯ ⲧⲓⲙⲏ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲣⲟⲥ.
25 A kì yóò sì ṣé àwọn ẹnu ibodè rẹ̀ rárá ní ọ̀sán: nítorí ki yóò si òru níbẹ̀.
ⲕ̅ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⲛⲉⲥⲡⲩⲗⲱⲛ ⳿ⲛⲛⲟⲩ⳿ϣⲑⲁⲙ ⳿ⲙⲡⲓ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲛⲉ ⳿ⲉϫⲱⲣϩ ϣⲱⲡⲓ ⳿ⲙⲙⲁⲩ.
26 Wọ́n ó sì máa mú ògo àti ọlá àwọn orílẹ̀-èdè wá sínú rẹ̀.
ⲕ̅ⲋ̅ⲉⲩ⳿ⲉ⳿ⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲓⲉⲑⲛⲟⲥ ⲛⲉⲙ ⲡⲟⲩⲱⲟⲩ ⲛⲉⲙ ⲡⲟⲩⲧⲁⲓ⳿ⲟ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲣⲟⲥ.
27 Ohun aláìmọ́ kan ki yóò sì wọ inú rẹ̀ rárá, tàbí ohun tí ń ṣiṣẹ́ ìríra àti èké; bí kò ṣe àwọn tí a kọ sínú ìwé ìyè Ọ̀dọ́-àgùntàn.
ⲕ̅ⲍ̅⳿ⲛⲛⲉ ⳿ϩⲗⲓ ⲉϥⲥⲱϥ ϣⲉ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲣⲟⲥ ⲛⲉⲙ ⲛⲏⲉⲧ⳿⳿ⲓⲣⲓ ⳿ⲛϩⲁⲛⲥⲱϥ ⳿ⲛⲛⲉ ⲙⲉⲑⲛⲟⲩϫ ⳿ⲓ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲣⲟⲥ ⳿ⲉⲃⲏⲗ ⳿ⲉⲛⲏⲉⲧ⳿ⲥϧⲏⲟⲩⲧ ϩⲓ ⲡⲓϫⲱⲙ ⳿ⲛⲧⲉ ⳿ⲡⲱⲛϧ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲓϩⲓⲏⲃ

< Revelation 21 >