< Revelation 18 >

1 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí mo sì rí angẹli mìíràn, ó ń ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ wá ti òun ti agbára ńlá; ilẹ̀ ayé sì ti ipa ògo rẹ̀ mọ́lẹ̀.
تَدَنَنْتَرَں سْوَرْگادْ اَوَروہَنْ اَپَرَ ایکو دُوتو مَیا درِشْٹَح سَ مَہاپَراکْرَمَوِشِشْٹَسْتَسْیَ تیجَسا چَ پرِتھِوِی دِیپْتا۔
2 Ó sì kígbe ní ohùn rara, wí pé: “Babeli ńlá ṣubú! Ó ṣubú! Ó sì di ibùjókòó àwọn ẹ̀mí èṣù, àti ihò fún ẹ̀mí àìmọ́ gbogbo, àti ilé fún ẹyẹ àìmọ́ gbogbo, ilé fún ẹranko ìríra àti àìmọ́ gbogbo.
سَ بَلَوَتا سْوَرینَ واچَمِمامْ اَگھوشَیَتْ پَتِتا پَتِتا مَہابابِلْ، سا بھُوتاناں وَسَتِح سَرْوّیشامْ اَشُچْیاتْمَناں کارا سَرْوّیشامْ اَشُچِیناں گھرِنْیانانْچَ پَکْشِناں پِنْجَرَشْچابھَوَتْ۔
3 Nítorí nípa ọtí wáìnì ìrunú àgbèrè rẹ̀ ni gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ṣubú. Àwọn ọba ayé sì ti bá a ṣe àgbèrè, àti àwọn oníṣòwò ayé sì di ọlọ́rọ̀ nípa ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọ̀bìà rẹ̀.”
یَتَح سَرْوَّجاتِییاسْتَسْیا وْیَبھِچارَجاتاں کوپَمَدِراں پِیتَوَنْتَح پرِتھِوْیا راجانَشْچَ تَیا سَہَ وْیَبھِچارَں کرِتَوَنْتَح پرِتھِوْیا وَنِجَشْچَ تَسْیاح سُکھَبھوگَباہُلْیادْ دھَناڈھْیَتاں گَتَوَنْتَح۔
4 Mo sì gbọ́ ohùn mìíràn láti ọ̀run wá, wí pé: “‘Ẹ ti inú rẹ̀ jáde, ẹ̀yin ènìyàn mi,’ kí ẹ ma bá a ṣe alábápín nínú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, kí ẹ ma bà á sì ṣe gbà nínú ìyọnu rẹ̀.
تَتَح پَرَں سْوَرْگاتْ مَیاپَرَ ایشَ رَوَح شْرُتَح، ہے مَمَ پْرَجاح، یُویَں یَتْ تَسْیاح پاپانامْ اَںشِنو نَ بھَوَتَ تَسْیا دَنْڈَیشْچَ دَنْڈَیُکْتا نَ بھَوَتَ تَدَرْتھَں تَتو نِرْگَچّھَتَ۔
5 Nítorí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ ga títí dé ọ̀run, Ọlọ́run sì ti rántí àìṣedéédéé rẹ̀.
یَتَسْتَسْیاح پاپانِ گَگَنَسْپَرْشانْیَبھَوَنْ تَسْیا اَدھَرْمَّکْرِیاشْچیشْوَرینَ سَںسْمرِتاح۔
6 San an fún un, àní bí òun tí san án fún ní, kí ó sì ṣe e ni ìlọ́po méjì fún un gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀, nínú ago náà tí o ti kún, òun ni kí ẹ sì kún fún un ni méjì.
پَرانْ پْرَتِ تَیا یَدْوَدْ وْیَوَہرِتَں تَدْوَتْ تاں پْرَتِ وْیَوَہَرَتَ، تَسْیاح کَرْمَّناں دْوِگُنَپھَلانِ تَسْیَے دَتَّ، یَسْمِنْ کَںسے سا پَرانْ مَدْیَمْ اَپایَیَتْ تَمیوَ تَسْیاح پانارْتھَں دْوِگُنَمَدْیینَ پُورَیَتَ۔
7 Níwọ́n bí o ti yin ara rẹ̀ lógo tó, tí ó sì hùwà wọ̀bìà, níwọ̀n bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ dá a lóró kí ẹ sì fún un ní ìbànújẹ́; nítorí tí ó wí ní ọkàn rẹ̀ pé, ‘Mo jókòó bí ọbabìnrin, èmi kì sì í ṣe opó, èmí kì yóò sì rí ìbànújẹ́ láé.’
تَیا یاتْمَشْلاگھا یَشْچَ سُکھَبھوگَح کرِتَسْتَیو رْدْوِگُنَو یاتَناشوکَو تَسْیَے دَتَّ، یَتَح سا سْوَکِییانْتَحکَرَنے وَدَتِ، راجْنِیوَدْ اُپَوِشْٹاہَں ناناتھا نَ چَ شوکَوِتْ۔
8 Nítorí náà, ní ọjọ́ kan ni ìyọnu rẹ̀ yóò dé, ikú, àti ìbìnújẹ́, àti ìyàn; a ó sì fi iná sun ún pátápátá: nítorí pé alágbára ni Olúwa Ọlọ́run tí ń ṣe ìdájọ́ rẹ̀.
تَسْمادْ دِوَسَ ایکَسْمِنْ مارِیدُرْبھِکْشَشوچَنَیح، سا سَماپْلوشْیَتے نارِی دھْیَکْشْیَتے وَہْنِنا چَ سا؛ یَدْ وِچارادھِپَسْتَسْیا بَلَوانْ پْرَبھُرِیشْوَرَح،
9 “Àti àwọn ọba ayé, tí ó ti ń bá a ṣe àgbèrè, tiwọn sì ń hùwà wọ̀bìà, yóò sì pohùnréré ẹkún lé e lórí, nígbà tí wọn bá wo èéfín ìjóná rẹ̀.
وْیَبھِچارَسْتَیا سارْدّھَں سُکھَبھوگَشْچَ یَیح کرِتَح، تے سَرْوَّ ایوَ راجانَسْتَدّاہَدھُومَدَرْشَناتْ، پْرَرودِشْیَنْتِ وَکْشاںسِ چاہَنِشْیَنْتِ باہُبھِح۔
10 Wọ́n ó dúró ní òkèrè réré nítorí ìbẹ̀rù iṣẹ́ oró rẹ̀, wọn ó máa wí pé: “‘Ègbé! Ègbé, ni fún ìlú ńlá náà, Babeli ìlú alágbára nì! Nítorí ní wákàtí kan ni ìdájọ́ rẹ dé!’
تَسْیاسْتَے رْیاتَنابھِیتے رْدُورے سْتھِتْویدَمُچْیَتے، ہا ہا بابِلْ مَہاسْتھانَ ہا پْرَبھاوانْوِتے پُرِ، ایکَسْمِنْ آگَتا دَنْڈے وِچاراجْنا تْوَدِییَکا۔
11 “Àwọn oníṣòwò ayé sì ń sọkún, wọn sì ń ṣọ̀fọ̀ lórí rẹ̀, nítorí pé ẹnikẹ́ni kò rà ọjà wọn mọ́.
میدِنْیا وَنِجَشْچَ تَسْیاح کرِتے رُدَنْتِ شوچَنْتِ چَ یَتَسْتیشاں پَنْیَدْرَوْیانِ کیناپِ نَ کْرِییَنْتے۔
12 Ọjà wúrà, àti ti fàdákà, àti ti òkúta iyebíye, àti ti perli, àti ti aṣọ ọ̀gbọ̀ wíwẹ́, àti tí elése àlùkò, àti ti ṣẹ́dà, àti ti òdòdó, àti ti gbogbo igi olóòórùn dídùn, àti ti olúkúlùkù ohun èlò tí a fi igi iyebíye ṣe, àti ti idẹ, àti ti irin, àti ti òkúta mabu.
پھَلَتَح سُوَرْنَرَوپْیَمَنِمُکْتاح سُوکْشْمَوَسْتْرانِ کرِشْنَلوہِتَواساںسِ پَٹَّوَسْتْرانِ سِنْدُورَوَرْنَواساںسِ چَنْدَنادِکاشْٹھانِ گَجَدَنْتینَ مَہارْگھَکاشْٹھینَ پِتَّلَلَوہابھْیاں مَرْمَّرَپْرَسْتَرینَ وا نِرْمِّتانِ سَرْوَّوِدھَپاتْرانِ
13 Àti ti Kinamoni, àti ti onírúurú ohun olóòórùn dídùn, àti ti ohun ìkunra, àti tí tùràrí, àti ti ọtí wáìnì, àti ti òróró, àti ti ìyẹ̀fun dáradára, àti ti alikama, àti ti ẹran ńlá, àti ti àgùntàn, àti ti ẹṣin, àti ti kẹ̀kẹ́, àti ti ẹrú, àti ti ọkàn ènìyàn.
تْوَگیلا دھُوپَح سُگَنْدھِدْرَوْیَں گَنْدھَرَسو دْراکْشارَسَسْتَیلَں شَسْیَچُورْنَں گودھُومو گاوو میشا اَشْوا رَتھا داسییا مَنُشْیَپْراناشْچَیتانِ پَنْیَدْرَوْیانِ کیناپِ نَ کْرِییَنْتے۔
14 “Àti àwọn èso tí ọkàn rẹ̀ ń ṣe. Ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ sí, si lọ kúrò lọ́dọ̀ rẹ, àti ohun gbogbo tí ó dùn tí ó sì dára ṣègbé mọ́ ọ lójú, kì yóò sì tún rí wọn mọ́ láé.
تَوَ مَنوبھِلاشَسْیَ پھَلاناں سَمَیو گَتَح، تْوَتّو دُورِیکرِتَں یَدْیَتْ شوبھَنَں بھُوشَنَں تَوَ، کَداچَنَ تَدُدّیشو نَ پُنَ رْلَپْسْیَتے تْوَیا۔
15 Àwọn oníṣòwò nǹkan wọ̀nyí, tí a ti ipa rẹ̀ sọ di ọlọ́rọ̀, yóò dúró ní òkèrè réré nítorí ìbẹ̀rù iṣẹ́ oró rẹ̀, wọn o máa sọkún, wọ́n ó sì máa ṣọ̀fọ̀,
تَدْوِکْریتارو یے وَنِجَسْتَیا دھَنِنو جاتاسْتے تَسْیا یاتَنایا بھَیادْ دُورے تِشْٹھَنَتو رودِشْیَنْتِ شوچَنْتَشْچیدَں گَدِشْیَنْتِ
16 wí pé: “‘Ègbé! Ègbé, ni fún ìlú ńlá nì, tí a wọ̀ ní aṣọ ọ̀gbọ̀ wíwẹ́, àti ti elése àlùkò, àti ti òdòdó, àti ti a sì fi wúrà ṣe ní ọ̀ṣọ́, pẹ̀lú òkúta iyebíye àti peali!
ہا ہا مَہاپُرِ، تْوَں سُوکْشْمَوَسْتْرَیح کرِشْنَلوہِتَوَسْتْرَیح سِنْدُورَوَرْنَواسوبھِشْچاچّھادِتا سْوَرْنَمَنِمُکْتابھِرَلَنْکرِتا چاسِیح،
17 Nítorí pé ní wákàtí kan ni ọrọ̀ ti o pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ di asán!’ “Àti olúkúlùkù ẹni tí ń rin ojú omi lọ sí ibikíbi, àti àwọn ti ń ṣiṣẹ́ nínú ọkọ àwọn ti ń ṣòwò ojú Òkun dúró ní òkèrè réré,
کِنْتْویکَسْمِنْ دَنْڈے سا مَہاسَمْپَدْ لُپْتا۔ اَپَرَں پوتاناں کَرْنَدھاراح سَمُوہَلوکا ناوِکاح سَمُدْرَوْیَوَسایِنَشْچَ سَرْوّی
18 wọ́n sì kígbe nígbà tí wọ́n rí èéfín jíjóná rẹ́, wí pé, ‘Ìlú wo ni o dàbí ìlú yìí?’
دُورے تِشْٹھَنْتَسْتَسْیا داہَسْیَ دھُومَں نِرِیکْشَمانا اُچَّیحسْوَرینَ وَدَنْتِ تَسْیا مَہانَگَرْیّاح کِں تُلْیَں؟
19 Wọ́n sì kú ekuru sí orí wọn, wọ́n kígbe, wọ́n sọkún, wọn sì ń ṣọ̀fọ̀, wí pé: “‘Ègbé! Ègbé, ni fún ìlú ńlá náà, nínú èyí tí a sọ gbogbo àwọn tí ó ni ọkọ̀ ní Òkun di ọlọ́rọ̀ nípa ohun iyebíye rẹ̀! Nítorí pé ni wákàtí kan, a sọ ọ́ di ahoro.’
اَپَرَں سْوَشِرَحسُ مرِتِّکاں نِکْشِپْیَ تے رُدَنْتَح شوچَنْتَشْچوچَّیحسْوَرینیدَں وَدَنْتِ ہا ہا یَسْیا مَہاپُرْیّا باہُلْیَدھَنَکارَناتْ، سَمْپَتِّح سَنْچِتا سَرْوَّیح سامُدْرَپوتَنایَکَیح، ایکَسْمِنّیوَ دَنْڈے سا سَمْپُورْنوچّھِنَّتاں گَتا۔
20 “Yọ̀ lórí rẹ̀, ìwọ ọ̀run! Ẹ yọ̀, ẹ̀yin ènìyàn Ọlọ́run! Ẹ yọ̀, ẹ̀yin aposteli mímọ́ àti wòlíì! Nítorí Ọlọ́run ti gbẹ̀san yín lára rẹ̀ nítorí ìdájọ́ tí ó gbé ka orí rẹ.”
ہے سْوَرْگَواسِنَح سَرْوّے پَوِتْراح پْریرِتاشْچَ ہے۔ ہے بھاوِوادِنو یُویَں کرِتے تَسْیاح پْرَہَرْشَتَ۔ یُشْماکَں یَتْ تَیا سارْدّھَں یو وِوادَح پُرابھَوَتْ۔ دَنْڈَں سَمُچِتَں تَسْیَ تَسْیَے وْیَتَرَدِیشْوَرَح۔۔
21 Angẹli alágbára kan sì gbé òkúta kan sókè, ó dàbí ọlọ ńlá, ó sì jù ú sínú Òkun, wí pé: “Báyìí ní a ó fi agbára ńlá bí i Babeli ìlú ńlá ni wó, a kì yóò sì rí i mọ́ láé.
اَنَنْتَرَمْ ایکو بَلَوانْ دُوتو برِہَتْپیشَنِیپْرَسْتَرَتُلْیَں پاشانَمیکَں گرِہِیتْوا سَمُدْرے نِکْشِپْیَ کَتھِتَوانْ، اِیدرِگْبَلَپْرَکاشینَ بابِلْ مَہانَگَرِی نِپاتَیِشْیَتے تَتَسْتَسْیا اُدّیشَح پُنَ رْنَ لَپْسْیَتے۔
22 Àti ohùn àwọn aludùùrù, àti ti àwọn olórin, àti ti àwọn afunfèrè, àti ti àwọn afùnpè, ni a kì yóò sì gbọ́ nínú rẹ mọ́ rara; àti olúkúlùkù oníṣọ̀nà ohunkóhun ni a kì yóò sì rí nínú rẹ mọ́ láé. Àti ìró ọlọ ní a kì yóò sì gbọ́ mọ̀ nínú rẹ láé;
وَلَّکِیوادِناں شَبْدَں پُنَ رْنَ شْروشْیَتے تْوَیِ۔ گاتھاکانانْچَ شَبْدو وا وَںشِیتُورْیّادِوادِناں۔ شِلْپَکَرْمَّکَرَح کو پِ پُنَ رْنَ دْرَکْشْیَتے تْوَیِ۔ پیشَنِیپْرَسْتَرَدھْوانَح پُنَ رْنَ شْروشْیَتے تْوَیِ۔
23 Àti ìmọ́lẹ̀ fìtílà ni kì yóò sì tàn nínú rẹ̀ mọ́ láé; a kì yóò sì gbọ́ ohùn ọkọ ìyàwó àti ti ìyàwó nínú rẹ mọ́ láé: nítorí pé àwọn oníṣòwò rẹ̀ ni àwọn ẹni ńlá ayé; nítorí pé nípa ọ̀ṣọ́ rẹ̀ ní a fi tàn orílẹ̀-èdè gbogbo jẹ.
دِیپَسْیاپِ پْرَبھا تَدْوَتْ پُنَ رْنَ دْرَکْشْیَتے تْوَیِ۔ نَ کَنْیاوَرَیوح شَبْدَح پُنَح سَںشْروشْیَتے تْوَیِ۔ یَسْمانْمُکھْیاح پرِتھِوْیا یے وَنِجَسْتےبھَوَنْ تَوَ۔ یَسْماچَّ جاتَیَح سَرْوّا موہِتاسْتَوَ مایَیا۔
24 Àti nínú rẹ̀ ní a gbé ri ẹ̀jẹ̀ àwọn wòlíì, àti ti àwọn ènìyàn mímọ́, àti ti gbogbo àwọn tí a pa lórí ilẹ̀ ayé.”
بھاوِوادِپَوِتْراناں یاوَنْتَشْچَ ہَتا بھُوِ۔ سَرْوّیشاں شونِتَں تیشاں پْراپْتَں سَرْوَّں تَوانْتَرے۔۔

< Revelation 18 >