< Revelation 17 >

1 Ọ̀kan nínú àwọn angẹli méje náà tí ó ní ìgò méje wọ̀n-ọn-nì sì wá, ó sì ba mi sọ̀rọ̀ wí pé, “Wá níhìn-ín; èmi ó sì fi ìdájọ́ àgbèrè ńlá ní tí ó jókòó lórí omi púpọ̀ han ọ,
Yumu gwa wantumintumi wa kumpindi saba walii, yawaweriti na mabakuli saba kiziti na kang'ambiriti, “Gwizi na neni hanukulanguziyi utoza yakapananitwi mndiyandiya mkulu ulii, yakalivagiti pambeku na mashi gavuwa.
2 ẹni tí àwọn ọba ayé bá ṣe àgbèrè, tí a sì fi ọtí wáìnì àgbèrè rẹ̀ pa àwọn tí ń gbé inú ayé.”
Wafalumi wa pasipanu watenditi uhumba pamuhera nayomberi na wantu yawalikala pasipanu walowera divayi ya uhumba wakuwi.”
3 Ó sì gbé mi nínú ẹ̀mí lọ sí aginjù: mo sì rí obìnrin kan ó jókòó lórí ẹranko aláwọ̀ òdòdó kan tí ó kún fún orúkọ ọ̀rọ̀-òdì, ó ní orí méje àti ìwo mẹ́wàá.
Shakapanu Rohu gwa Mlungu kanjegiti na ntumintumi gwa kumpindi kanjegiti kushiwara. Kweni aku numwona mdala kalivagiti pankanyama mkalipa msheri. Nkanyama mkalipa ayu kaweriti kalembwa kila pahala matawu ga kumwigilanga Mlungu, kaweriti na mituwi saba na magoli lilongu.
4 A sì fi aṣọ elése àlùkò àti aṣọ òdòdó wọ obìnrin náà, a sì fi wúrà àti òkúta iyebíye àti perli ṣe é ní ọ̀ṣọ́, ó ní ago wúrà kan ní ọwọ́ rẹ̀, tí ó kún fún ìríra àti fún ẹ̀gbin àgbèrè rẹ̀;
Mdala ayu kaweriti kavala nguwu langi ya zambalawu na nsheri, kaweriti kalihelipiziya kwa zaabu na vintu vinyawitwi kwa mabuwi ga beyi nkulu na mabuwi ga lulu. Mumawoku mwakuwi kaweriti na lutekeru lwa zaabu lwaluweliti lumema makalaliru na vitwatira vidoda vya uhumba wakuwi.
5 àti níwájú rẹ̀ ni orúkọ kan tí a kọ: Ohun ìjìnlẹ̀ Babeli ńlá ìyá àwọn panṣágà àti àwọn ohun ìríra ayé.
Pashiwunji shakuwi palembitwi visoweru vya litawu lyana mana ya bada, “Babiloni mkulu, mawu gwa wandiyandiya na gwa vitwatira vyoseri vya kukalaziya nentu pasipanu.”
6 Mo sì rí obìnrin náà mu ẹ̀jẹ̀ àwọn ènìyàn mímọ́, àti ẹ̀jẹ̀ àwọn ajẹ́rìí ikú Jesu ní àmuyó. Nígbà tí mo sì rí i, ẹnu yà mi gidigidi.
Numwona mdala ayu kalowera mwazi gwa wantu wa Mlungu na mwazi gwa wantu yawalagitwi toziya ya kuwera wakapitawu kwa Yesu. Panumwoniti nulikangashiti nentu.
7 Angẹli sì wí fún mi pé, “Nítorí kí ni ẹnu ṣe yà ọ́? Èmi ó sọ ti ìjìnlẹ̀ obìnrin náà fún ọ, àti ti ẹranko tí ó gùn, ti ó ní orí méje àti ìwo mẹ́wàá.
Kumbiti ntumintumi gwa kumpindi kang'ambira, “Iwera hashi gwankulikangasha. Neni hanukugambiri mana ya bada yaififikiti ya mdala ayu na nkanyama mkalipa ayu yakampapiti, nkanyama mkalipa yakawera na mituwi saba na magoli lilongu.
8 Ẹranko tí ìwọ ri nì, o ti wà, kò sì ṣí mọ́, yóò sì ti inú ọ̀gbun gòkè wá, yóò sì lọ sínú ìparun rẹ. Àwọn olùgbé ayé ti a kọ orúkọ wọn sínú ìwé iye láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé, nígbà tí wọn ń wò ẹranko tí o ti wà, tí kò sì ṣí mọ́, tí ó sì ń bọ̀ wá, ẹnu si ya wọn. (Abyssos g12)
Nkanyama mkalipa ayu yagumwoniti, kaweriti mkomu pakwanja kumbiti vinu kahowa. Kayi kapakwegera kulawa mulirindi lyalihera upeleru kugenda kuharabisiwa. Wantu yawalikala pasipanu hawalikangashi, wantu woseri matawu gawu galembitwi ndiri mushintola sha ukomu kwanjira kunyawa kwa pasipanu, hawalikangashi kumwona nkanyama mkalipa ayu kwanja kalikaliti, shakapanu kafuwa na vinu hakalawili kayi. (Abyssos g12)
9 “Níhìn-ín ni ìtumọ̀ tí o ní ọgbọ́n wà. Orí méje ni òkè ńlá méje ni, lórí èyí tí obìnrin náà jókòó.
“Panu pafiruwa mahala na luhala! Mituwi saba ayi ndo vigongu saba mdala ayu kalivagiti. Mituwi ayi viraa ndo wafalumi saba.
10 Ọba méje sì ní wọn: àwọn márùn-ún ṣubú, ọ̀kan ń bẹ, ọ̀kan ìyókù kò sì tí ì dé; nígbà tí ó bá sì dé, yóò dúró fún ìgbà kúkúrú.
Pakati pa wafalumi saba, wamhanu yawagamiliti kala, yumu kankali kankukolamlima na yumonga ulii kankali kwiza na pakasoka kafiruwa hakakolimlima kwa shipindi shididini.
11 Ẹranko tí ó sì ti wà, tí kò sì ṣí, òun náà sì ni ẹ̀kẹjọ, ó sì ti inú àwọn méje náà wá, ó sì lọ sí ìparun.
Na nkanyama mkalipa ayu yakaweriti kankulikala kwanja, kumbiti vinu kalikala ndiri kayi ndo mfalumi gwa nani na yomberi viraa ndo yumu gwawu gwa walii saba na kuharabisiwa.
12 “Ìwo mẹ́wàá tí ìwọ sì rí ni ọba mẹ́wàá ni wọn, tí wọn kò ì ti gba ìjọba; ṣùgbọ́n wọn gba àṣẹ bí ọba pẹ̀lú ẹranko náà fún wákàtí kan.
“Magoli galii lilongu yagugawoniti ndo wafalumi lilongu weni haweniyanji kukolamlima. Kumbiti hawapananwi uwezu wa kukolamlima kwa shipindi sha saa yimu pamuhera na nkanyama mkalipa ulii.
13 Àwọn wọ̀nyí ní inú kan, wọ́n yóò sì fi agbára àti ọlá wọn fún ẹranko náà.
Woseri awa lilongu wawera na nfiru yimu na hawamupanani nkanyama mkalipa ulii makakala na uwezu wawu.
14 Àwọn wọ̀nyí ni yóò si máa bá Ọ̀dọ́-Àgùntàn jagun, Ọ̀dọ́-Àgùntàn náà yóò sì ṣẹ́gun wọn: nítorí òun ni Olúwa àwọn Olúwa, àti ọba àwọn ọba: àwọn tí ó sì wà pẹ̀lú rẹ̀, tí a pè, tí a yàn, tí wọ́n sì jẹ́ olóòtítọ́ yóò sì ṣẹ́gun pẹ̀lú.”
Hawalikomangi na Mwanakondolu na kumbiti Mwanakondolu pamuhera na walii yakawashemiti na kuwasyagula weni ndo waminika hakawakanki toziya yomberi ndo Mtuwa gwa watuwa na Mfalumi gwa wafalumi.”
15 Ó sì wí fún mi pé, “Àwọn omi tí ìwọ ti rí ni, níbi tí àgbèrè náà jókòó, àwọn ènìyàn àti ẹ̀yà àti orílẹ̀ àti onírúurú èdè ni wọ́n.
Ntumintumi gwa kumpindi kang'ambira vilaa, “Mashi galii yagugawoniti palii pakalivagiti mndiyandiya ulii, ndo mapinga ga wantu wa kulawa kila isi, ukowu na luga.
16 Àti ìwo mẹ́wàá tí ìwọ rí, àti ẹranko náà, àwọn wọ̀nyí ni yóò kórìíra àgbèrè náà, wọn ó sì sọ ọ́ di ahoro àti ẹni ìhòhò, wọn ó sì jẹ ẹran-ara rẹ̀, wọn ó sì fi iná sun ún pátápátá.
Na magoli lilongu galii gagugawoniti na nkanyama mkalipa ulii hawamkalalili mndiyandiya ulii. Hawatoli kila shintu shakawera nashu na kumleka shivula hera, hawalii vinofu vya nshimba yakuwi na kumlunguziya kwa motu.
17 Nítorí Ọlọ́run ti fi sínú ọkàn wọn láti mú ìfẹ́ rẹ̀ ṣẹ, láti ní inú kan, àti láti fi ìjọba wọn fún ẹranko náà, títí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run yóò fi ṣẹ.
Toziya Mlungu kalekera mumyoyu mwawu nfiru ya kutenda mafiliru gakuwi, su walijimirani womberi kwa womberi na kumpanana nkanyama mkalipa ayu makakala ga kukolamlima mpaka galii gagatakuliti Mlungu pagatendeka.
18 Obìnrin tí ìwọ rí ní ìlú ńlá ni, tí ń jẹ ọba lórí àwọn ọba ilẹ̀ ayé.”
“Na mdala ulii yagumwoniti ndo lushi lulii lukulu lwaluwera na ukukolamlima wawafalumi wa pasipanu.”

< Revelation 17 >