< Revelation 17 >
1 Ọ̀kan nínú àwọn angẹli méje náà tí ó ní ìgò méje wọ̀n-ọn-nì sì wá, ó sì ba mi sọ̀rọ̀ wí pé, “Wá níhìn-ín; èmi ó sì fi ìdájọ́ àgbèrè ńlá ní tí ó jókòó lórí omi púpọ̀ han ọ,
Iri nimi malaika tangba wa basia nji kukon tagban ba ba ye tre nime ndi ye toro hukuci kikle ntran wa a son nitu nma'a
2 ẹni tí àwọn ọba ayé bá ṣe àgbèrè, tí a sì fi ọtí wáìnì àgbèrè rẹ̀ pa àwọn tí ń gbé inú ayé.”
Wa ba chu bi meme ba wa mba niwu, mba ihi wu (faskanci) wa bison ni meme ba hwa niwu.
3 Ó sì gbé mi nínú ẹ̀mí lọ sí aginjù: mo sì rí obìnrin kan ó jókòó lórí ẹranko aláwọ̀ òdòdó kan tí ó kún fún orúkọ ọ̀rọ̀-òdì, ó ní orí méje àti ìwo mẹ́wàá.
Niki maleka a ban ne ni mi ruhu hi ni miji, i mika iwari si son nitu samban narhu (daba ) wa nde gbugbuwu bi ya irjhi-grji (sabo), ba shu nimi ma. Nmarhu nima rhu a he ni itu tangban mba njon wlen.
4 A sì fi aṣọ elése àlùkò àti aṣọ òdòdó wọ obìnrin náà, a sì fi wúrà àti òkúta iyebíye àti perli ṣe é ní ọ̀ṣọ́, ó ní ago wúrà kan ní ọwọ́ rẹ̀, tí ó kún fún ìríra àti fún ẹ̀gbin àgbèrè rẹ̀;
Iwa'a srukpi u ma shunaya mba samban nda klo kpama ni zinariya, wlotita hi bi, mba (lu'u-lwai. Njiniwoma, kofi u zinariya wa a shuni kpi bi kahon bi bababi kpatimeme u faskanci.
5 àti níwájú rẹ̀ ni orúkọ kan tí a kọ: Ohun ìjìnlẹ̀ Babeli ńlá ìyá àwọn panṣágà àti àwọn ohun ìríra ayé.
Ni ci ma banba nde ri u riri, kikle babila, ihi bi ntran mba bi kpi meme u meme.
6 Mo sì rí obìnrin náà mu ẹ̀jẹ̀ àwọn ènìyàn mímọ́, àti ẹ̀jẹ̀ àwọn ajẹ́rìí ikú Jesu ní àmuyó. Nígbà tí mo sì rí i, ẹnu yà mi gidigidi.
Mito iwaa a hwa ni iyi wu tsatsra inji bi Irji mba iyi wa ba wuuba nitu Yesu. Niwa mi too a, mi ti mamaki. I maleka a tre nime, Nitu ngye wuti mamaki?
7 Angẹli sì wí fún mi pé, “Nítorí kí ni ẹnu ṣe yà ọ́? Èmi ó sọ ti ìjìnlẹ̀ obìnrin náà fún ọ, àti ti ẹranko tí ó gùn, ti ó ní orí méje àti ìwo mẹ́wàá.
Mi tsro kpibi keniriri nitu iwaa mbau nmarhu (beast) wa a hlusinji, nmarhu wa a heni itu tangban mba njon wloa a.
8 Ẹranko tí ìwọ ri nì, o ti wà, kò sì ṣí mọ́, yóò sì ti inú ọ̀gbun gòkè wá, yóò sì lọ sínú ìparun rẹ. Àwọn olùgbé ayé ti a kọ orúkọ wọn sínú ìwé iye láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé, nígbà tí wọn ń wò ẹranko tí o ti wà, tí kò sì ṣí mọ́, tí ó sì ń bọ̀ wá, ẹnu si ya wọn. (Abyssos )
Nmarhu wa wu too ahea, ana la hema, i ba ati weiweire u rhuye rhini holon juju wa ana heni nchina. Niki anchi tsra ni halaka. Biwa ba kii ni meme, biwa bana nha ndemba ni vunvu bi sisren rhini nchime u gbugbunla na, bati mamaki to nmaa nitu ana he ni nkpuri, nda na la he zizan na, nde la niye. (Abyssos )
9 “Níhìn-ín ni ìtumọ̀ tí o ní ọgbọ́n wà. Orí méje ni òkè ńlá méje ni, lórí èyí tí obìnrin náà jókòó.
Kpeyi yi wuti mre nda he ni hikima Itu tangbanba bati ngblu tangban wa iwaa ni son nitumba.
10 Ọba méje sì ní wọn: àwọn márùn-ún ṣubú, ọ̀kan ń bẹ, ọ̀kan ìyókù kò sì tí ì dé; nígbà tí ó bá sì dé, yóò dúró fún ìgbà kúkúrú.
Bana bi chu tangban ngame. Ichu ton ba kuheye, iri rhihe, i irimba a rhihe u ye i anita ye ani fe son u ton fiime.
11 Ẹranko tí ó sì ti wà, tí kò sì ṣí, òun náà sì ni ẹ̀kẹjọ, ó sì ti inú àwọn méje náà wá, ó sì lọ sí ìparun.
Nmarhu wa ana hea, ndama he zizan na, nikima me a hi chu u tandra. Ana wu tangban a ndani hi ni halaka mba.
12 “Ìwo mẹ́wàá tí ìwọ sì rí ni ọba mẹ́wàá ni wọn, tí wọn kò ì ti gba ìjọba; ṣùgbọ́n wọn gba àṣẹ bí ọba pẹ̀lú ẹranko náà fún wákàtí kan.
Njon wlon wa mitoba, bana chu wlon wa ba rhihe kpa gbuma, i ba kpa too chu wu nton ri nhani nmarhua.
13 Àwọn wọ̀nyí ní inú kan, wọ́n yóò sì fi agbára àti ọlá wọn fún ẹranko náà.
Biyi bana bi mren ri i ba ka gbengblen mba iko mba nu nmahua.
14 Àwọn wọ̀nyí ni yóò si máa bá Ọ̀dọ́-Àgùntàn jagun, Ọ̀dọ́-Àgùntàn náà yóò sì ṣẹ́gun wọn: nítorí òun ni Olúwa àwọn Olúwa, àti ọba àwọn ọba: àwọn tí ó sì wà pẹ̀lú rẹ̀, tí a pè, tí a yàn, tí wọ́n sì jẹ́ olóòtítọ́ yóò sì ṣẹ́gun pẹ̀lú.”
Ba taku ni vren ntmaa. I vren ntma a ni rhini kua nitu wawuyyi hi bachi u ba Baci mba ichuu bichu-baba biwa ba he niwu ba yoba, chuba, nda bi kri gbangban nihua.
15 Ó sì wí fún mi pé, “Àwọn omi tí ìwọ ti rí ni, níbi tí àgbèrè náà jókòó, àwọn ènìyàn àti ẹ̀yà àti orílẹ̀ àti onírúurú èdè ni wọ́n.
Maleka a tre nime “imma wa bi to, wa ntran a santuma, nji, kpaadi, meme mba ilanba ba hea.
16 Àti ìwo mẹ́wàá tí ìwọ rí, àti ẹranko náà, àwọn wọ̀nyí ni yóò kórìíra àgbèrè náà, wọn ó sì sọ ọ́ di ahoro àti ẹni ìhòhò, wọn ó sì jẹ ẹran-ara rẹ̀, wọn ó sì fi iná sun ún pátápátá.
Njon wlon wa mu tooa, babayi ba nmarhu bi wa ba kran intrana. Ba du son ni nklema mba ni ngre, ba du tan nma kpama i ba gon ni lu pempeme.
17 Nítorí Ọlọ́run ti fi sínú ọkàn wọn láti mú ìfẹ́ rẹ̀ ṣẹ, láti ní inú kan, àti láti fi ìjọba wọn fún ẹranko náà, títí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run yóò fi ṣẹ.
Nitu Irjhi a yo ni sronmba ndi duba kpa ndu u son ma, nda kpanyeme niba ni du nu gbengblen mla u mulki ni nmarhua rhi du lantre Irji ye ka he toki.
18 Obìnrin tí ìwọ rí ní ìlú ńlá ni, tí ń jẹ ọba lórí àwọn ọba ilẹ̀ ayé.”
Iwaa wa wutoo ahi kikle igbu wa a heni gbengblen mulki nitu ba chu bi meme.