< Revelation 16 >

1 Mo sì gbọ́ ohùn ńlá kan láti inú tẹmpili wá, ń wí fún àwọn angẹli, méje nì pé, “Ẹ lọ, ẹ sì tú ago ìbínú Ọlọ́run wọ̀n-ọn-nì sí orí ayé.”
ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲉⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛ⳿ⲥⲙⲏ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ⲉⲥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⳿ⲛⲛⲓⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ϫⲉ ⲙⲁϣⲉ ⲛⲱⲧⲉⲛ ϫⲉϣ ⲛⲉⲧⲉⲛⲫⲩⲁⲗⲏ ⳿ⲉⲡⲉⲥⲏⲧ ⳿ⲛⲧⲉ ⳿ⲡⲉⲙⲃⲟⲛ ⳿ⲙⲫϯ.
2 Èkínní sì lọ, ó sì tú ago tirẹ̀ sí orílẹ̀ ayé: egbò kíkẹ̀ tí ó sì díbàjẹ́ sì dá àwọn ènìyàn tí ó ní àmì ẹranko náà, àti àwọn tí ń foríbalẹ̀ fún àwòrán rẹ̀.
ⲃ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁϥϣⲉ ⲛⲁϥ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲓϩⲟⲩⲓⲧ ⳿ⲛⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲁϥϫⲉϣ ⲧⲉϥⲫⲩⲁⲗⲏ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲡⲓⲕⲁϩⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲁ ⲟⲩϣⲁϣⲓ ⲉϥϩⲱⲟⲩ ϣⲱⲡⲓ ϧⲉⲛ ⲛⲓⲣⲱⲙⲓ ⲛⲏⲉⲧⲧⲟⲃ ⳿ⲉⲡⲓⲑⲏⲣⲓⲟⲛ ⲛⲉⲙ ⲛⲏⲉⲑⲟⲩⲱϣⲧ ⳿ⲛⲧⲉϥϩⲩⲕⲱⲛ.
3 Èkejì sì tú ago sínú Òkun; ó sì dàbí ẹ̀jẹ̀ òkú ènìyàn, gbogbo ọkàn alààyè sì kú nínú Òkun.
ⲅ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁ ⲡⲓⲙⲁϩⲃ̅ ⳿ⲛⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲁϥϫⲱϣ ⳿ⲛⲧⲉϥⲫⲩⲁⲗⲏ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⳿ⲫⲓⲟⲙ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥⲉⲣ⳿ⲥⲛⲟϥ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲙⲫⲁ ⲟⲩⲣⲉϥⲙⲱⲟⲩⲧ ⲟⲩⲟϩ ⲯⲩⲭⲏ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲉⲧⲟⲛϧ ⲁⲩⲙⲟⲩ ϧⲉⲛ ⳿ⲫⲓⲟⲙ.
4 Ẹ̀kẹta sì tú ago tirẹ̀ sínú odò, àti sí orísun àwọn omi; wọ́n sì di ẹ̀jẹ̀.
ⲇ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁ ⲡⲓⲙⲁϩⲅ̅ ⳿ⲛⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲁϥϫⲱϣ ⳿ⲛⲧⲉϥⲫⲩⲁⲗⲏ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲛⲓⲓⲁⲣⲱⲟⲩ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲙⲟⲩⲙⲓ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩⲉⲣ⳿ⲥⲛⲟϥ.
5 Mo sì gbọ́ angẹli tí ó n wí pé: “Olódodo ni ìwọ ninu gbogbo ìdájọ́ wọ̀nyí, ìwọ ẹni tí ó n bẹ àti tí ó tí wa, Ẹni Mímọ́ nítorí tí ìwọ ṣe ìdájọ́ bẹ́ẹ̀.
ⲉ̅ⲁⲓⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲉⲡⲓⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲓⲙⲱⲟⲩ ⲉϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⳿ⲛⲑⲟⲕ ⲟⲩ⳿ⲑⲙⲏⲓ ⲫⲏⲉⲧϣⲟⲡ ⲟⲩⲟϩ ⲫⲏ ⲉⲛⲁϥϣⲟⲡ ϫⲉ ⲁⲕϯϩⲁⲡ ⳿ⲉⲛⲁⲓ.
6 Nítorí tí wọ́n ti ta ẹ̀jẹ̀ àwọn ènìyàn mímọ́ àti ti àwọn wòlíì sílẹ̀, ìwọ sì fi ẹ̀jẹ̀ fún wọn mu; èyí yìí ní ó yẹ wọ́n.”
ⲋ̅ϫⲉ ⲡⲓ⳿ⲥⲛⲟϥ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲓⲙⲁⲣⲧⲩⲣⲟⲥ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲡⲣⲟⲫⲏⲧⲏⲥ ⲁⲩⲫⲟⲛϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲁⲕϯ ⳿ⲥⲛⲟϥ ⲛⲱⲟⲩ ⳿ⲉⲥⲱ ϫⲉ ⲥⲉⲙ⳿ⲡϣⲁ.
7 Mo sì gbọ́ ti pẹpẹ ń ké wí pé: “Bẹ́ẹ̀ ni, Olúwa Ọlọ́run Olódùmarè, òtítọ́ àti òdodo ní ìdájọ́ rẹ.”
ⲍ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲉⲡⲓⲙⲁ⳿ⲛⲉⲣϣⲱⲟⲩϣⲓ ⲉϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⲥⲉ Ⲡ⳪ ⲫϯ ⲡⲓⲡⲁⲛⲧⲟⲕⲣⲁⲧⲱⲣ ⲡⲓ⳿ⲑⲙⲏⲓ ⲛⲉⲕϩⲁⲡ ⲧⲏⲣⲟⲩ ϩⲁⲛⲙⲉⲑⲙⲏⲓ ⲛⲉ.
8 Ẹ̀kẹrin sì tú ago tirẹ̀ sórí oòrùn; a sì yọ̀ǹda fún un láti fi iná jó ènìyàn lára.
ⲏ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓⲙⲁϩⲇ̅ ⳿ⲛⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲁϥϫⲱϣ ⳿ⲛⲧⲉϥⲫⲩⲁⲗⲏ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⳿ⲫⲣⲏ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩⲧⲏⲓⲥ ⲛⲁϥ ⳿ⲉⲉⲣⲕⲁⲩⲙⲁ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲛⲓⲣⲱⲙⲓ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛⲕⲁⲩⲙⲁ.
9 A sì fi ooru ńlá jó àwọn ènìyàn lára, wọ́n sì sọ̀rọ̀-òdì sí orúkọ Ọlọ́run, ẹni tí ó ní agbára lórí ìyọnu wọ̀nyí: wọn kò sì ronúpìwàdà láti fi ògo fún un.
ⲑ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩⲉⲣⲕⲁⲩⲙⲁ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲓⲣⲱⲙⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩϫⲉⲟⲩⲁ ⳿ⲉ⳿ⲫⲣⲁⲛ ⳿ⲙⲫϯ ⲫⲏⲉⲧⲉ ⲟⲩⲟⲛⲧⲉϥ ⲉⲣϣⲓϣⲓ ⳿ⲙⲙⲁⲩ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲛⲁⲓⲉⲣϧⲟⲧ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙⲡⲟⲩⲉⲣⲙⲉⲧⲁⲛⲟⲓⲛ ⳿ⲉϯⲱⲟⲩ ⳿ⲙⲫϯ.
10 Ẹ̀karùnún sì tú ago tirẹ̀ sórí ìtẹ́ ẹranko náà; ilẹ̀ ọba rẹ̀ sì ṣókùnkùn; wọ́n sì ń gé ahọ́n wọn jẹ́ nítorí ìrora.
ⲓ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓⲙⲁϩⲉ̅ ⳿ⲛⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲁϥϫⲱϣ ⳿ⲛⲧⲉϥⲫⲩⲁⲗⲏ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲡⲓ⳿ⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲓⲑⲏⲣⲓⲟⲛ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲥⲉⲣⲭⲁⲕⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲧⲉϥⲙⲉⲧⲟⲩⲣⲟ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲁⲩⲟⲩⲟϫⲟⲩⲉϫ ⳿ⲛⲛⲟⲩⲗⲁⲥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲡⲓ⳿ⲙⲕⲁϩ.
11 Wọ́n sì sọ̀rọ̀-òdì sí Ọlọ́run ọ̀run nítorí ìrora wọn àti nítorí egbò wọn, wọ́n kò sì ronúpìwàdà iṣẹ́ wọn.
ⲓ̅ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩϫⲉⲟⲩ⳿ⲁ ⳿ⲉⲫϯ ⳿ⲛⲧⲉ ⳿ⲧⲫⲉ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲡⲓ⳿ⲙⲕⲁϩ ⲛⲉⲙ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲛⲟⲩ⳿ϩⲃⲏ ⲟⲩ⳿ⲓ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙⲡⲟⲩⲉⲣⲙⲉⲧⲁⲛⲟⲓⲛ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲛⲟⲩ⳿ϩⲃⲏⲟⲩ⳿ⲓ ⲉⲧϩⲱⲟⲩ.
12 Ẹ̀kẹfà sì tu ìgò tirẹ̀ sórí odò ńlá Eufurate; omi rẹ̀ sì gbẹ, kí a lè pèsè ọ̀nà fún àwọn ọba láti ìlà-oòrùn wá.
ⲓ̅ⲃ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓⲙⲁϩ ⳿ⲛⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲁϥϫⲱϣ ⳿ⲛⲧⲉϥⲫⲩⲁⲗⲏ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⳿ⲫⲓⲁⲣⲟ ⲡⲓⲛⲓϣϯ ⲡⲓⲉⲩⲫⲣⲁⲧⲏ ⲥ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥϣⲱⲟⲩ⳿ⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲓⲙⲱⲟⲩ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲉϥⲥⲟⲃϯ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲓⲙⲱⲓⲧ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲓⲟⲩⲣⲱⲟⲩ ⲉⲧⲥⲁⲛⲓⲙⲁ ⳿ⲛϣⲁⲓ ⳿ⲛⲧⲉ ⳿ⲫⲣⲏ.
13 Mo sì rí àwọn ẹ̀mí àìmọ́ mẹ́ta bí ọ̀pọ̀lọ́, wọ́n ti ẹnu dragoni náà àti ẹnu ẹranko náà àti ẹnu wòlíì èké náà jáde wá.
ⲓ̅ⲅ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲣⲱϥ ⳿ⲙⲡⲓ⳿ⲇⲣⲁⲕⲱⲛ ⲛⲉⲙ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲣⲱϥ ⳿ⲙⲡⲓⲑⲏⲣⲓⲟⲛ ⲛⲉⲙ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲣⲱϥ ⳿ⲙⲡⲓⲯⲉⲩⲇⲟ⳿ⲡⲣⲟⲫⲏⲧⲏⲥ ⳿ⲉⲅ̅ ⳿ⲙⲡ͞ⲛⲁ̅ ⲉⲩⲥⲱϥ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛϩⲁⲛ⳿ⲭⲣⲟⲩⲣ.
14 Nítorí ẹ̀mí èṣù ni wọ́n, tí ń ṣe iṣẹ́ ìyanu, àwọn tí ń jáde lọ sọ́dọ̀ àwọn ọba gbogbo ilẹ̀ ayé, láti gbá wọn jọ sí ogun ọjọ́ ńlá Ọlọ́run Olódùmarè.
ⲓ̅ⲇ̅ϩⲁⲛⲡ͞ⲛⲁ̅ ⲅⲁⲣ ⳿ⲛⲓϧ ⲛⲉ ⲉⲩ⳿ⲓⲣⲓ ⳿ⲛϩⲁⲛⲙⲏ ⲓⲛⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲛⲓⲟⲩⲣⲱⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉ ⳿ⲡⲕⲁϩⲓ ⲉⲑⲟⲩⲱⲧⲟⲩ ⳿ⲉ⳿ⲡⲡⲟⲗⲉⲙⲟⲥ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲓⲛⲓϣϯ ⳿ⲛ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉ ⲫϯ ⲡⲓⲡⲁⲛⲧⲟⲕⲣⲁⲧⲱⲣ.
15 “Kíyèsi i; ń bọ̀ bi olè, ìbùkún ni fún ẹni tí ń ṣọ́nà, tí ó sì ń pa aṣọ rẹ̀ mọ́, kí ó má bá a rìn ni ìhòhò, wọn a sì rí ìtìjú rẹ̀.”
ⲓ̅ⲉ̅ϩⲏⲡⲡⲉ ϯⲛⲏⲟⲩ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛⲟⲩⲣⲉϥ ϭⲓⲟⲩ⳿ⲓ ⲱⲟⲩ⳿ⲛⲓⲁⲧϥ ⳿ⲙⲫⲏⲉⲑⲛⲁⲣⲱⲓⲥ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲉϥⲁⲣⲉϩ ⳿ⲉⲛⲉϥ⳿ϩⲃⲱⲥ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲉϥ⳿ϣⲧⲉⲙⲙⲟϣⲓ ⲉϥⲃⲏϣ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲟⲩⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲡⲉϥϣⲓⲡⲓ.
16 Ó sì gbá wọn jọ́ sí ibìkan tí a ń pè ní Amagedoni ní èdè Heberu.
ⲓ̅ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁϥⲑⲟⲩⲱⲧⲟⲩ ⲉⲩⲙⲁ ⲉⲩⲙⲟⲩϯ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⳿ⲙⲙⲉⲧϩⲉⲃⲣⲉⲟⲥ ϫⲉ ⲉⲣⲙⲁⲕⲉⲇⲱⲛ.
17 Èkeje si tú ago tirẹ̀ sí ojú ọ̀run; ohùn ńlá kan sì ti inú tẹmpili jáde láti ibi ìtẹ́, wí pé, “Ó parí!”
ⲓ̅ⲍ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓⲙⲁϩⲍ̅ ⳿ⲛⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲁϥϫⲱϣ ⳿ⲛⲧⲉϥⲫⲩⲁⲗⲏ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲡⲓⲁⲏⲣ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥⲉϣ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛ⳿ϧⲣⲱⲟⲩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲡⲓⲉⲣⲫⲉⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲁ ⲡⲓ⳿ⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⲉϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⲁϥϣⲱⲡⲓ.
18 Mọ̀nàmọ́ná sì kọ, a sì gbọ́ ohùn, àrá sì sán, ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá sì ṣẹ̀, irú èyí tí kò ṣẹ̀ ri láti ìgbà tí ènìyàn ti wà lórí ilẹ̀, irú ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá bẹ́ẹ̀, tí ó sì lágbára tó bẹ́ẹ̀.
ⲓ̅ⲏ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩϣⲱⲡⲓ ⳿ⲛϫⲉ ϩⲁⲛϧⲁⲣⲁⲃⲁⲓ ⲛⲉⲙ ϩⲁⲛ⳿ⲥⲙⲏ ⲛⲉⲙ ϩⲁⲛⲥⲉⲧⲉⲃⲣⲏϫ ⲟⲩⲟϩ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲙⲙⲟⲛⲙⲉⲛ ⲁϥϣⲱⲡⲓ ⳿ⲙⲡⲉ ⲟⲩⲟⲛ ϣⲱⲡⲓ ⳿ⲙⲡⲉϥⲣⲏϯ ⲓⲥϫⲉⲛ ⲉⲧⲁ ⲣⲱⲙⲓ ϣⲱⲡⲓ ϩⲓϫⲉⲛ ⳿ⲡⲕⲁϩⲓ.
19 Ìlú ńlá náà sì pín sí ipa mẹ́ta, àwọn orílẹ̀-èdè sì ṣubú: Babeli ńlá sì wá sí ìrántí níwájú Ọlọ́run, láti fi ago ọtí wáìnì ti ìrunú ìbínú rẹ̀ fún un.
ⲓ̅ⲑ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲥϣⲱⲡⲓ ⳿ⲛϫⲉ ϯⲛⲓϣϯ ⳿ⲙⲃⲁⲕⲓ ⳿ⲉⲅ̅ ⳿ⲛⲧⲟⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲓⲃⲁⲕⲓ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲓⲉⲑⲛⲟⲥ ⲁⲩϩⲉⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲃⲁⲃⲩⲗⲱⲛ ϯⲛⲓϣϯ ⲁⲩⲉⲣⲡⲉⲥⲙⲉⲩⲓ ⳿ⲙⲡⲉ⳿ⲙⲑⲟ ⳿ⲙⲫϯ ⳿ⲉϯ ⲛⲁⲥ ⳿ⲙⲡⲓⲁⲫⲟⲧ ⳿ⲛⲏⲣⲡ ⳿ⲛⲧⲉ ⳿ⲡⲉⲙⲃⲟⲛ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲓϫⲱⲛⲧ.
20 Olúkúlùkù erékùṣù sì sálọ, a kò sì ri àwọn òkè ńlá mọ́.
ⲕ̅ⲟⲩⲟϩ ⲛⲏⲥⲟⲥ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲁⲩⲫⲱⲧ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲓⲧⲱⲟⲩ ⳿ⲙⲡⲟⲩϫⲉⲙ ⲡⲟⲩⲙⲁ.
21 Yìnyín ńlá, tí ọ̀kọ̀ọ̀kan rẹ̀ tó tálẹ́ǹtì ní ìwọ̀n, sì bọ́ lù àwọn ènìyàn láti ọ̀run wà, àwọn ènìyàn sì sọ̀rọ̀-òdì sí Ọlọ́run nítorí ìyọnu yìnyín náà; nítorí tí ìyọnu rẹ̀ náà pọ̀ gidigidi.
ⲕ̅ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ϩⲁⲛⲁⲗ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛϩⲁⲛϫⲓⲛ ϭⲱⲣ ⳿ⲛϣⲓ ⲁⲩ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲛⲓⲣⲱⲙⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲁ ⲛⲓⲣⲱⲙⲓ ϫⲉⲟⲩ⳿ⲁ ⳿ⲉⲫϯ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲡⲓⲉⲣϧⲟⲧ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲓⲁⲗ ⲉⲧⲟϣ ⳿ⲉⲙⲁϣⲱ

< Revelation 16 >