< Revelation 14 >

1 Mo sì wo, si kíyèsi i, Ọ̀dọ́-Àgùntàn náà dúró lórí òkè Sioni, àti pẹ̀lú rẹ̀ ọ̀kẹ́ méje ó lé ẹgbàajì ènìyàn; wọ́n ní orúkọ rẹ̀, àti orúkọ baba rẹ̀ tí a kọ sí iwájú orí wọn.
ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲡⲓϩⲓⲏⲃ ⲉϥⲟϩⲓ ⳿ⲉⲣⲁⲧϥ ϩⲓϫⲉⲛ ⲡⲓⲧⲱⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉ ⲥⲓⲱⲛ ⲛⲉⲙ ⲣ̅ⲙ̅ⲇ̅ ⳿ⲛϣⲟ ⲉⲩⲭⲏ ⲛⲉⲙⲁϥ ⲉⲣⲉ ⲡⲉϥⲣⲁⲛ ⲛⲉⲙ ⳿ⲫⲣⲁⲛ ⳿ⲙⲡⲉϥⲓⲱⲧ ⲉϥ⳿ⲥϧⲏⲟⲩⲧ ϩⲓ ⲧⲟⲩⲧⲉϩⲛⲓ.
2 Mo sì gbọ́ ohùn kan láti ọ̀run wá, bí ariwo omi púpọ̀, àti bí sísán àrá ńlá, mo sì gbọ́ àwọn aludùùrù tí wọn ń lu dùùrù.
ⲃ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲉⲟⲩ⳿ⲥⲙⲏ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛϧⲁⲣⲁⲃⲁⲓ ⲟⲩⲟϩ ϯ⳿ⲥⲙⲏ ⲉⲧⲁⲓⲥⲟⲑⲙⲉⲥ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛϩⲁⲛⲣⲉϥⲉⲣⲟⲩⲱⲓⲛⲓ.
3 Wọ́n sì ń kọ bí ẹni pé orin tuntun níwájú ìtẹ́ náà, àti níwájú àwọn ẹ̀dá alààyè mẹ́rin n nì àti àwọn àgbà náà, kò sì ṣí ẹni tí o lè kọ orin náà, bí kò ṣe àwọn ọ̀kẹ́ méje ó lé ẹgbàajì ènìyàn, tí a tí rà padà láti inú ayé wá.
ⲅ̅ⲉⲩϩⲱⲥ ϧⲉⲛ ⲟⲩϩⲱⲇⲏ ⳿ⲙⲃⲉⲣⲓ ⳿ⲙⲡⲉ⳿ⲙⲑⲟ ⳿ⲙⲡⲓ⳿ⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⲛⲉⲙ ⲡⲉ⳿ⲙⲑⲟ ⳿ⲙⲡⲓⲇ̅ ⳿ⲛⲍⲱⲟⲛ ⲛⲉⲙ ⲛⲓ⳿ⲡⲣⲉⲥⲃⲩⲧⲉⲣⲟⲥ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙⲡⲉ ⳿ϩⲗⲓ ϫⲉⲙϫⲟⲙ ⳿ⲉ⳿ⲉⲙⲓ ⳿ⲉϯϩⲱⲇⲏ ⳿ⲉⲃⲏⲗ ⳿ⲉⲡⲓⲣ̅ⲙ̅ⲇ̅ ⳿ⲛϣⲟ ⲛⲏⲉⲧⲁⲩϣⲟⲡⲟⲩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲡⲕⲁϩⲓ.
4 Àwọn wọ̀nyí ni a kò fi obìnrin sọ di èérí, nítorí tí wọ́n jẹ́ wúńdíá. Àwọn wọ̀nyí ni o ń tọ Ọ̀dọ́-àgùntàn náà lẹ́yìn níbikíbi tí o bá ń lọ. Àwọn wọ̀nyí ni a rà padà láti inú àwọn ènìyàn wá, wọ́n jẹ́ àkọ́so fún Ọlọ́run àti fún Ọ̀dọ́-Àgùntàn náà.
ⲇ̅ⲛⲁⲓ ⲛⲉ ⲛⲏⲉⲧⲉ ⳿ⲙⲡⲟⲩⲑⲱⲗⲉⲃ ⳿ⲛⲛⲟⲩ⳿ϩⲃⲱⲥ ⲛⲉⲙ ⳿ⲥϩⲓⲙⲓ ϩⲁⲛⲡⲁⲣⲑⲉⲛⲟⲥ ⲅⲁⲣ ⲛⲉ ⲛⲁⲓ ⲛⲉ ⲛⲏⲉⲑⲙⲟϣⲓ ⲛⲉⲙ ⲡⲓϩⲓⲏⲃ ⳿ⲉⲡⲓⲙⲁ ⲉⲧⲉϥⲛⲁϣⲉ ⲛⲁϥ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⲛⲁⲓ ⲛⲉ ⲛⲏⲉⲧⲁⲩϣⲟⲡⲟⲩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲛⲓⲣⲱⲙⲓ ⳿ⲛⲁⲡⲁⲣⲭⲏ ⳿ⲙⲫϯ ⲛⲉⲙ ⲡⲓϩⲓⲏⲃ.
5 A kò sì rí èké lẹ́nu wọn, wọn jẹ́ aláìlábùkù.
ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙⲡⲟⲩϫⲉⲙ ⳿ϩⲗⲓ ⳿ⲙⲙⲉⲑⲛⲟⲩϫ ϧⲉⲛ ⲣⲱⲟⲩ ⲥⲉⲧⲟⲩⲃⲏⲟⲩⲧ ⲅⲁⲣ.
6 Mo sì rí angẹli mìíràn ń fò ní àárín méjì ọ̀run, pẹ̀lú ìyìnrere àìnípẹ̀kun láti wàásù fún àwọn tí ń gbé orí ilẹ̀ ayé, àti fún gbogbo orílẹ̀, àti ẹ̀yà, àti èdè, àti ènìyàn. (aiōnios g166)
ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲕⲉⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲉϥϩⲏⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲑⲙⲏϯ ⳿ⲛ⳿ⲧⲫⲉ ⳿ⲉⲟⲩⲟⲛ ⲟⲩⲉⲩⲁⲅⲅⲉⲗⲓⲟⲛ ⳿ⲛⲉⲛⲉϩ ⳿ⲛⲧⲟⲧϥ ⲉϥϩⲓϣⲉⲛⲛⲟⲩϥⲓ ⳿ⲛⲛⲏⲉⲧϣⲟⲡ ϩⲓϫⲉⲛ ⳿ⲡⲕⲁϩⲓ ⲛⲉⲙ ⳿ϣⲗⲟⲗ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲛⲉⲙ ⲫⲩⲗⲏ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲛⲉⲙ ⲗⲁⲟⲥ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲛⲉⲙ ⲗⲁⲥ ⲛⲓⲃⲉⲛ. (aiōnios g166)
7 Ó ń wí ni ohùn rara pé, “Ẹ bẹ̀rù Ọlọ́run, kí ẹ sì fi ògo fún un, nítorí tí wákàtí ìdájọ́ rẹ̀ dé: ẹ sì foríbalẹ̀ fún ẹni tí o dá ọ̀run, àti ayé, àti Òkun, àti àwọn orísun omi!”
ⲍ̅ⲉϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛ⳿ϧⲣⲱⲟⲩ ϫⲉ ⲁⲣⲓϩⲟϯ ϧⲁ⳿ⲧϩⲏ ⳿ⲙⲫϯ ⲟⲩⲟϩ ⲙⲁⲱⲟⲩ ⲛⲁϥ ϫⲉ ⲁⲥ⳿ⲓ ⳿ⲛϫⲉ ϯⲟⲩⲛⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲉϥϩⲁⲡ ⲟⲩⲟϩ ⲟⲩⲱϣⲧ ⳿ⲙⲫⲏⲉⲧⲁϥⲑⲁⲙⲓ⳿ⲉ ⳿ⲧⲫⲉ ⲛⲉⲙ ⳿ⲡⲕⲁϩⲓ ⲛⲉⲙ ⳿ⲫⲓⲟⲙ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲙⲱⲟⲩ.
8 Angẹli mìíràn sì tẹ̀lé e, ó ń wí pé, “o ṣubú, Babeli ńlá ṣubú, èyí ti o tí ń mú gbogbo orílẹ̀-èdè mu nínú ọtí wáìnì àìmọ́ àgbèrè rẹ̀!”
ⲏ̅ⲟⲩⲟϩ ⲕⲉⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⳿ⲙⲙⲁϩⲃ̅ ⲁϥⲙⲟϣⲓ ⳿ⲛⲥⲱϥ ⲉϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⲁⲥϩⲉⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲃⲁⲃⲩⲗⲱⲛ ϯⲛⲓϣϯ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲡⲏⲣⲡ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲉ⳿ⲙⲃⲟⲛ ⳿ⲛⲧⲉ ⲧⲉⲥⲡⲟⲣⲛⲓⲁ ⲁⲩϩⲉⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲓⲉⲑⲛⲟⲥ ⲧⲏⲣⲟⲩ.
9 Angẹli mìíràn, ẹ̀kẹta, sì tẹ̀lé wọn, ó ń wí ni ohùn rara pé, “Bí ẹnikẹ́ni bá ń foríbalẹ̀ fún ẹranko náà àti àwòrán rẹ̀, tí ó sì gba àmì sí iwájú orí rẹ̀ tàbí sí ọwọ́ rẹ̀.
ⲑ̅ⲟⲩⲟϩ ⲕⲉⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⳿ⲙⲙⲁϩⲅ̅ ⲁϥⲙⲟϣⲓ ⳿ⲛⲥⲱⲟⲩ ⲉϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⲫⲏⲉⲑⲛⲁⲟⲩⲱϣⲧ ⳿ⲙⲡⲓⲑⲏⲣⲓⲟⲛ ⲛⲉⲙ ⲧⲉϥϩⲩⲕⲱⲛ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲉϥⲧⲟⲃϥ ⳿ⲉⲧⲉϥⲧⲉϩⲛⲓ ⲓⲉ ⲧⲉϥϫⲓϫ.
10 Òun pẹ̀lú yóò mú nínú ọtí wáìnì ìbínú Ọlọ́run, tí a dà ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ sínú ago ìrunú rẹ̀; a ó sì fi iná sulfuru dá a lóró níwájú àwọn angẹli mímọ́, àti níwájú Ọ̀dọ́-àgùntàn.
ⲓ̅⳿ⲛⲑⲟϥ ⲉⲑⲛⲁⲥⲱ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲡⲓⲏⲣⲡ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲉ⳿ⲙⲃⲟⲛ ⳿ⲙⲫϯ ⲫⲏⲉⲧⲑⲏⲧ ⳿ⲛⲏⲣⲡ ⳿ⲛⲁⲕⲣⲁⲧⲟⲛ ϧⲉⲛ ⲡⲓ⳿ⲁⲫⲟⲧ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲉϥϫⲱⲛⲧ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲩ⳿ⲉⲉⲣⲃⲁⲥⲁⲛⲓⲍⲓⲛ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ϧⲉⲛ ⲟⲩ ⳿ⲭⲣⲱⲙ ⲛⲉⲙ ⲟⲩⲑⲏⲛ ⳿ⲙⲡⲉ⳿ⲙⲑⲟ ⳿ⲛⲛⲓⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲛⲉⲙ ⲡⲉ⳿ⲙⲑⲟ ⳿ⲙⲡⲓϩⲓⲏⲃ.
11 Èéfín ìdálóró wọn ń lọ sókè títí láéláé wọn kò sì ní ìsinmi ni ọ̀sán àti ní òru, àwọn tí ń foríbalẹ̀ fún ẹranko náà àti fún àwòrán rẹ̀, àti ẹnikẹ́ni tí o ba sì gba àmì orúkọ rẹ̀.” (aiōn g165)
ⲓ̅ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓ⳿ⲭⲣⲉⲙⲧⲥ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲟⲩ⳿ⲧϩⲉⲙⲕⲟ ⲉϥ⳿ⲉϣⲉ ⳿ⲉ⳿ⲡϣⲱⲓ ϣⲁ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϫⲉ ⳿ⲙⲙⲟⲛ ⳿ⲙⲧⲟⲛ ⳿ⲙⲙⲁⲩ ⳿ⲙⲡⲓ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⲛⲉⲙ ⲡⲓⲉϫⲱⲣϩ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲏⲉⲑⲛⲁⲟⲩⲱϣⲧ ⳿ⲙⲡⲓⲑⲏⲣⲓⲟⲛ ⲛⲉⲙ ⲧⲉϥϩⲩⲕⲱⲛ ⲛⲉⲙ ⲫⲏⲉⲑⲛⲁϭⲓ ⳿ⲙⲡⲓϣⲱⲗϩ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲉϥⲣⲁⲛ. (aiōn g165)
12 Níhìn-ín ni sùúrù àwọn ènìyàn mímọ́ gbé wà: àwọn tí ń pa òfin Ọlọ́run àti ìgbàgbọ́ Jesu mọ́.
ⲓ̅ⲃ̅ⲫⲏ ⲇⲉ ⲉⲑⲛⲁ⳿ⲁⲙⲟⲛⲓ ⳿ⲛⲧⲟⲧϥ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲁⲅⲓⲟⲥ ⲛⲏⲉⲑⲛⲁ⳿ⲁⲣⲉϩ ⳿ⲉⲛⲓⲉⲛⲧⲟⲗⲏ ⳿ⲛⲧⲉ ⲫϯ ⲛⲉⲙ ⲡⲓⲛⲁϩϯ ⳿ⲛⲧⲉ Ⲓⲏ̅ⲥ̅ Ⲡⲭ̅ⲥ̅.
13 Mo sì gbọ́ ohùn kan láti ọ̀run wá ń wí fún mi pé, “Kọ̀wé rẹ̀, Alábùkún fún ni àwọn òkú tí o kú nínú Olúwa láti ìhín lọ.” Alábùkún ni wọ́n nítòótọ́, bẹ́ẹ̀ ni, Ẹ̀mí wí, “Nítorí tí wọn yóò sinmi kúrò nínú làálàá wọn, nítorí iṣẹ́ wọn ń tọ̀ wọn lẹ́yìn.”
ⲓ̅ⲅ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲉⲕⲉⲛⲓϣϯ ⳿ⲛ⳿ϧⲣⲱⲟⲩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ⲉϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⲱⲟⲩ⳿ⲛⲓⲁⲧⲟⲩ ⳿ⲛⲛⲓⲣⲉϥⲙⲱⲟⲩⲧ ϧⲉⲛ Ⲡ⳪ ⲁⲩϣⲁⲛⲧⲱⲟⲩⲛⲟⲩ ⲓⲥϫⲉⲛ ϯⲛⲟⲩ ⳿ϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲓⲡ͞ⲛⲁ̅ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲟⲩ⳿ⲙⲧⲟⲛ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ⲓⲥϫⲉⲛ ϯⲛⲟⲩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲛⲟⲩϧⲓⲥⲓ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲟⲩ⳿ϩⲃⲏⲟⲩ⳿ⲓ ⲉⲩ⳿ⲉⲙⲟϣⲓ ⳿ⲛⲥⲱⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲧⲉϥϭⲓⲙⲱⲓⲧ ϧⲁϫⲱⲟⲩ ⳿ⲉ⳿ϧⲣⲏⲓ ⳿ⲉⲟⲩⲙⲟⲩⲙⲓ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ⳿ⲛⲱⲛϧ.
14 Mo sì wo, sì kíyèsi i, ìkùùkuu àwọsánmọ̀ funfun kan, àti lórí ìkùùkuu àwọsánmọ̀ náà ẹnìkan jókòó tí o dàbí “ọmọ ènìyàn,” tí òun ti adé wúrà ní orí rẹ̀, àti dòjé mímú ni ọwọ́ rẹ̀.
ⲓ̅ⲇ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲟⲩϭⲏⲡⲓ ⲉⲥⲟⲩⲱⲃϣ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙ⳿ⲡϣⲱⲓ ϩⲓϫⲉⲛ ϯϭⲏⲡⲓ ⲉϥϩⲉⲙⲥⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲟⲩⲁⲓ ⲉϥⲟⲛⲓ ⳿ⲛⲟⲩϣⲏⲣⲓ ⳿ⲛⲣⲱⲙⲓ ⳿ⲉⲟⲩⲟⲛ ⲟⲩ⳿ⲭⲗⲟⲙ ⳿ⲛⲛⲟⲩⲃ ϩⲓϫⲱϥ ⳿ⲉⲟⲩⲟⲛ ⲟⲩⲥⲏϥⲓ ⲉⲥϩⲓⲟⲩ⳿ⲓ ϧⲉⲛ ⲧⲉϥϫⲓϫ.
15 Angẹli mìíràn sì tí inú tẹmpili jáde wa tí ń ké lóhùn rara sí ẹni tí ó jókòó lórí ìkùùkuu àwọsánmọ̀ náà pé, “Tẹ dòjé rẹ bọ̀ ọ́, kí ó sì máa kórè; nítorí àkókò àti kórè dé, nítorí ìkórè ayé ti gbó tán.”
ⲓ̅ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⲕⲉⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲁϥ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲡⲓⲉⲣⲫⲉⲓ ⲉϥⲱϣ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛ⳿ϧⲣⲱⲟⲩ ⲉϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⳿ⲙⲫⲏⲉⲧϩⲉⲙⲥⲓ ϩⲓϫⲉⲛ ϯϭⲏⲡⲓ ϫⲉ ⲟⲩⲱⲣⲡ ⳿ⲙⲡⲉⲕⲱⲥϧ ⲟⲩⲟϩ ⲱⲥϧ ϫⲉ ⲁⲥ⳿ⲓ ⳿ⲛϫⲉ ϯⲟⲩⲛⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉ ⳿ⲡⲱⲥϧ ⳿ⲙ⳿ⲡⲕⲁϩⲓ.
16 Ẹni tí ó jókòó lórí ìkùùkuu àwọsánmọ̀ náà sì tẹ dòjé rẹ̀ bọ orí ilẹ̀ ayé; a sì ṣe ìkórè ilẹ̀ ayé.
ⲓ̅ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ⲫⲏⲉⲧϩⲉⲙⲥⲓ ϩⲓϫⲉⲛ ϯϭⲏⲡⲓ ⲁϥⲟⲩⲱⲣⲡ ⳿ⲙⲡⲉϥⲱⲥϧ ϩⲓϫⲉⲛ ⲡⲓⲕⲁϩⲓ.
17 Angẹli mìíràn sì tí inú tẹmpili tí ń bẹ ni ọ̀run jáde wá, òun pẹ̀lú sì ní dòjé mímú, kan.
ⲓ̅ⲍ̅ⲟⲩⲟϩ ⲕⲉⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⳿ⲉⲁϥ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ⳿ⲉⲟⲩⲟⲛ ⲟⲩⲥⲏϥⲓ ⳿ⲛⲧⲟⲧϥ ⲉⲥϩⲓⲟⲩ⳿ⲓ.
18 Angẹli mìíràn sì tí ibi pẹpẹ jáde wá, tí ó ní agbára lórí iná; ó sì ké ni ohùn rara sí ẹni tí o ni dòjé mímú náà, wí pé, “Tẹ dòjé rẹ mímú bọ̀ ọ́, ki ó sì rẹ́ àwọn ìdì àjàrà ayé, nítorí àwọn èso rẹ̀ tí pọ́n.”
ⲓ̅ⲏ̅ⲟⲩⲟϩ ⲕⲉⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲁϥ⳿ⲓ ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲡⲓⲙⲁ⳿ⲛⲉⲣϣⲱⲟⲩϣⲓ ⳿ⲉⲟⲩⲟⲛ ⲟⲩⲉⲣϣⲓϣⲓ ⳿ⲛⲧⲉ ⲟⲩ⳿ⲭⲣⲱⲙ ⳿ⲛⲧⲟⲧϥ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥⲙⲟⲩϯ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛ⳿ϧⲣⲱⲟⲩ ⳿ⲉⲫⲏⲉⲧⲉ ϯⲥⲏϥⲓ ⲉⲧϩⲓⲟⲩ⳿ⲓ ⳿ⲛⲧⲟⲧϥ ⲉϥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⲟⲩⲱⲣⲡ ⳿ⲛⲧⲉⲕⲥⲏϥⲓ ⲉⲧϩⲓⲟⲩ⳿ⲓ ⲟⲩⲟϩ ϭⲉⲗ ⲡⲓ⳿ⲥⲙⲁϩ ⳿ⲛⲁⲗⲟⲗⲓ ⳿ⲛⲧⲉ ⳿ⲡⲕⲁϩⲓ.
19 Angẹli náà sì tẹ dòjé rẹ̀ bọ ilẹ̀ ayé, ó sì gé àjàrà ilẹ̀ ayé, ó sì kó o lọ sínú ìfúntí, ìfúntí ńlá ìbínú Ọlọ́run.
ⲓ̅ⲑ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁ ⲡⲓⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ϩⲓⲟⲩ⳿ⲓ ⳿ⲛⲧⲉϥⲥⲏ ϥⲓ ⳿ⲉ⳿ⲡⲕⲁϩⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥϭⲉⲗ ⲡⲓ⳿ⲁⲗⲟⲗⲓ ⳿ⲛⲧⲉ ⳿ⲡⲕⲁϩⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥϩⲓⲧϥ ⳿ⲉ⳿ϧⲣⲏⲓ ⳿ⲉϯⲛⲓϣϯ ⳿ⲛ⳿ϩⲣⲱⲧ ⳿ⲛⲧⲉ ⳿ⲡⲉⲙⲃⲟⲛ ⳿ⲙⲫϯ.
20 A sì tẹ ìfúntí náà lẹ́yìn òde ìlú náà, ẹ̀jẹ̀ sì ti inú ìfúntí náà jáde, ó sì ga sókè dé okùn ìjánu ẹṣin, èyí tí ìnàsílẹ̀ rẹ to ẹ̀gbẹjọ̀ ibùsọ̀.
ⲕ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁϥϩⲱⲙⲓ ⳿ⲛϯ⳿ϩⲣⲱⲧ ⲥⲁⲃⲟⲗ ⳿ⲛϯⲃⲁⲕⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲛϫⲉ ⲟⲩ⳿ⲥⲛⲟϥ ϧⲉⲛ ϯ⳿ϩⲣⲱⲧ ϣⲁ ⲛⲓⲭⲁⲗⲓⲛⲟⲩⲥ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲓ⳿ϩⲑⲱⲣ ⳿ⲛⲟⲩϣⲟ ⲛⲉⲙ ⲭ̅ ⳿ⲛ⳿ⲥⲧⲁⲇⲓⲟⲛ

< Revelation 14 >