< Revelation 12 >

1 Àmì ńlá kan sì hàn ni ọ̀run; obìnrin kan tí a fi oòrùn wọ̀ ní aṣọ, òṣùpá sì ń bẹ lábẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀, adé oníràwọ̀ méjìlá sì ń bẹ lórí rẹ̀.
تَتَح پَرَں سْوَرْگے مَہاچِتْرَں درِشْٹَں یوشِدیکاسِیتْ سا پَرِہِتَسُورْیّا چَنْدْرَشْچَ تَسْیاشْچَرَنَیورَدھو دْوادَشَتاراناں کِرِیٹَنْچَ شِرَسْیاسِیتْ۔
2 Ó sì lóyún, ó sì kígbe ni ìrọbí, ó sì wà ni ìrora àti bímọ.
سا گَرْبھَوَتِی سَتِی پْرَسَوَویدَنَیا وْیَتھِتارْتَّراوَمْ اَکَروتْ۔
3 Àmì mìíràn sì hàn ní ọ̀run; sì kíyèsi i, dragoni pupa ńlá kan, tí ó ní orí méje àti ìwo mẹ́wàá, àti adé méje ní orí rẹ̀.
تَتَح سْوَرْگے پَرَمْ ایکَں چِتْرَں درِشْٹَں مَہاناگَ ایکَ اُپاتِشْٹھَتْ سَ لوہِتَوَرْنَسْتَسْیَ سَپْتَ شِراںسِ سَپْتَ شرِنْگانِ شِرَحسُ چَ سَپْتَ کِرِیٹانْیاسَنْ۔
4 Ìrù rẹ̀ sì wọ́ ìdámẹ́ta àwọn ìràwọ̀ ní ojú ọ̀run, ó sì jù wọ́n sí ilẹ̀ ayé, dragoni náà sì dúró níwájú obìnrin náà tí ó fẹ́ bímọ, pé nígbà tí o bá bí i, kí òun lè pa ọmọ rẹ̀ jẹ.
سَ سْوَلانْگُولینَ گَگَنَسْتھَنَکْشَتْراناں ترِتِییاںشَمْ اَوَمرِجْیَ پرِتھِوْیاں نْیَپاتَیَتْ۔ سَ ایوَ ناگو نَوَجاتَں سَنْتانَں گْرَسِتُمْ اُدْیَتَسْتَسْیاح پْرَسَوِشْیَمانایا یوشِتو نْتِکے تِشْٹھَتْ۔
5 Ó sì bi ọmọkùnrin kan tí yóò fi ọ̀pá irin ṣe àkóso gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè, a sì gba ọmọ rẹ̀ lọ sókè sí ọ̀dọ̀ Ọlọ́run, àti sí orí ìtẹ́ rẹ̀.
سا تُ پُںسَنْتانَں پْرَسُوتا سَ ایوَ لَوہَمَیَراجَدَنْڈینَ سَرْوَّجاتِیشْچارَیِشْیَتِ، کِنْچَ تَسْیاح سَنْتانَ اِیشْوَرَسْیَ سَمِیپَں تَدِییَسِںہاسَنَسْیَ چَ سَنِّدھِمْ اُدّھرِتَح۔
6 Obìnrin náà sì sálọ sí aginjù, níbi tí a gbé ti pèsè ààyè sílẹ̀ dè é láti ọwọ́ Ọlọ́run wá, pé kí wọ́n máa bọ́ ọ níbẹ̀ ní ẹgbẹ̀fà ọjọ́ ó lé ọgọ́ta.
سا چَ یوشِتْ پْرانْتَرَں پَلایِتا یَتَسْتَتْریشْوَرینَ نِرْمِّتَ آشْرَمے شَشْٹھْیَدھِکَشَتَدْوَیادھِکَسَہَسْرَدِنانِ تَسْیاح پالَنینَ بھَوِتَوْیَں۔
7 Ogun sì ń bẹ ní ọ̀run: Mikaeli àti àwọn angẹli rẹ̀ bá dragoni náà jagun; dragoni sì jagun àti àwọn angẹli rẹ̀.
تَتَح پَرَں سْوَرْگے سَںگْرامَ اُپاپِشْٹھَتْ مِیکھاییلَسْتَسْیَ دُوتاشْچَ تینَ ناگینَ سَہایُدھْیَنْ تَتھا سَ ناگَسْتَسْیَ دُوتاشْچَ سَںگْرامَمْ اَکُرْوَّنْ، کِنْتُ پْرَبھَوِتُں ناشَکْنُوَنْ
8 Wọ́n kò sì lè ṣẹ́gun; bẹ́ẹ̀ ni a kò sì rí ipò wọn mọ́ ni ọ̀run.
یَتَح سْوَرْگے تیشاں سْتھانَں پُنَ رْناوِدْیَتَ۔
9 A sì lé dragoni ńlá náà jáde, ejò láéláé nì, tí a ń pè ni Èṣù, àti Satani, tí ń tan gbogbo ayé jẹ: a sì lé e jù sí ilẹ̀ ayé, a sì lé àwọn angẹli rẹ̀ jáde pẹ̀lú rẹ̀.
اَپَرَں سَ مَہاناگو رْتھَتو دِیاوَلَح (اَپَوادَکَح) شَیَتانَشْچَ (وِپَکْشَح) اِتِ نامْنا وِکھْیاتو یَح پُراتَنَح سَرْپَح کرِتْسْنَں نَرَلوکَں بھْرامَیَتِ سَ پرِتھِوْیاں نِپاتِتَسْتینَ سارْدّھَں تَسْیَ دُوتا اَپِ تَتْرَ نِپاتِتاح۔
10 Mo sì gbọ́ ohùn ńlá ní ọ̀run, wí pè: “Nígbà yìí ni ìgbàlà dé, àti agbára, àti ìjọba Ọlọ́run wá, àti ọlá àti Kristi rẹ̀. Nítorí a tí le olùfisùn àwọn arákùnrin wa jáde, tí o ń fi wọ́n sùn níwájú Ọlọ́run wa lọ́sàn án àti lóru.
تَتَح پَرَں سْوَرْگے اُچَّے رْبھاشَمانو رَوو یَں مَیاشْراوِ، تْرانَں شَکْتِشْچَ راجَتْوَمَدھُنَیویشْوَرَسْیَ نَح۔ تَتھا تینابھِشِکْتَسْیَ تْراتُح پَراکْرَمو بھَوَتْں۔۔ یَتو نِپاتِتو سْماکَں بھْراترِناں سو بھِیوجَکَح۔ یینیشْوَرَسْیَ نَح ساکْشاتْ تے دُوشْیَنْتَ دِوانِشَں۔۔
11 Wọ́n sì ti ṣẹ́gun rẹ̀ nítorí ẹ̀jẹ̀ ọ̀dọ́-àgùntàn náà, àti nítorí ọ̀rọ̀ ẹ̀rí wọn, wọn kò sì fẹ́ràn ẹ̀mí wọn àní títí dé ikú.
میشَوَتْسَسْیَ رَکْتینَ سْوَساکْشْیَوَچَنینَ چَ۔ تے تُ نِرْجِتَوَنْتَسْتَں نَ چَ سْنیہَمْ اَکُرْوَّتَ۔ پْرانوشْوَپِ سْوَکِیییشُ مَرَنَسْیَیوَ سَنْکَٹے۔
12 Nítorí náà ẹ máa yọ̀, ẹ̀yin ọ̀run, àti ẹ̀yin tí ń gbé inú wọn. Ègbé ni fún ayé àti Òkun; nítorí èṣù sọ̀kalẹ̀ tọ̀ yín wá ní ìbínú ńlá, nítorí ó mọ̀ pé ìgbà kúkúrú sá ni òun ní.”
تَسْمادْ آنَنْدَتُ سْوَرْگو ہرِشْیَنْتاں تَنِّوامِنَح۔ ہا بھُومِساگَرَو تاپو یُوامیواکْرَمِشْیَتِ۔ یُوَیورَوَتِیرْنو یَتْ شَیتانو تِیوَ کاپَنَح۔ اَلْپو مے سَمَیو سْتْییتَچّاپِ تیناوَگَمْیَتے۔۔
13 Nígbà tí dragoni náà rí pé a lé òun lọ sí ilẹ̀ ayé, ó ṣe inúnibíni sì obìnrin tí ó bí ọmọkùnrin náà.
اَنَنْتَرَں سَ ناگَح پرِتھِوْیاں سْوَں نِکْشِپْتَں وِلوکْیَ تاں پُتْرَپْرَسُوتاں یوشِتَمْ اُپادْرَوَتْ۔
14 A sì fi apá ìyẹ́ méjì tí idì ńlá náà fún obìnrin náà, pé kí ó fò lọ sí aginjù, sí ipò rẹ̀, níbi tí a ó gbe bọ ọ fún àkókò kan àti fún àwọn àkókò, àti fún ìdajì àkókò kúrò lọ́dọ̀ ejò náà.
تَتَح سا یوشِتْ یَتْ سْوَکِییَں پْرانْتَرَسْتھاشْرَمَں پْرَتْیُتْپَتِتُں شَکْنُیاتْ تَدَرْتھَں مَہاکُرَرَسْیَ پَکْشَدْوَیَں تَسْوَے دَتَّں، سا تُ تَتْرَ ناگَتو دُورے کالَیکَں کالَدْوَیَں کالارْدّھَنْچَ یاوَتْ پالْیَتے۔
15 Ejò náà sì tu omi jáde láti ẹnu rẹ̀ wá bí odò ńlá sẹ́yìn obìnrin náà, kí ó lè fi ìṣàn omi náà gbà á lọ.
کِنْچَ سَ ناگَسْتاں یوشِتَں سْروتَسا پْلاوَیِتُں سْوَمُکھاتْ نَدِیوَتْ تویانِ تَسْیاح پَشْچاتْ پْراکْشِپَتْ۔
16 Ilẹ̀ sì ran obìnrin náà lọ́wọ́, ilẹ̀ sì ya ẹnu rẹ̀, ó sì fi ìṣàn omi náà mú, tí dragoni náà tu jáde láti ẹnu rẹ̀ wá.
کِنْتُ میدِنِی یوشِتَمْ اُپَکُرْوَّتِی نِجَوَدَنَں وْیادایَ ناگَمُکھادْ اُدْگِیرْناں نَدِیمْ اَپِوَتْ۔
17 Dragoni náà sì bínú gidigidi sí obìnrin náà, ó sì lọ bá àwọn irú-ọmọ rẹ̀ ìyókù jagun, tí wọ́n ń pa òfin Ọlọ́run mọ̀, tí wọn sì di ẹ̀rí Jesu mú, Ó sì dúró lórí iyanrìn Òkun.
تَتو ناگو یوشِتے کْرُدّھوا تَدْوَںشَسْیاوَشِشْٹَلوکَیرَرْتھَتو یَ اِیشْوَرَسْیاجْناح پالَیَنْتِ یِیشوح ساکْشْیَں دھارَیَنْتِ چَ تَیح سَہَ یودّھُں نِرْگَتَوانْ۔

< Revelation 12 >