< Revelation 12 >

1 Àmì ńlá kan sì hàn ni ọ̀run; obìnrin kan tí a fi oòrùn wọ̀ ní aṣọ, òṣùpá sì ń bẹ lábẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀, adé oníràwọ̀ méjìlá sì ń bẹ lórí rẹ̀.
ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ⲓⲥ ϩⲏⲡⲡⲉ ⲁ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲙⲙⲏⲓⲛⲓ ⲁϥⲟⲩⲟⲛϩϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ⲟⲩ⳿ⲥϩⲓⲙⲓ ⲉⲥϫⲟⲗϩ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓⲓⲟϩ ⲥⲁⲡⲉⲥⲏⲧ ⳿ⲛⲛⲉⲥ ϭⲁⲗⲁⲩϫ ⲟⲩ⳿ⲭⲗⲟⲙ ⲉϥⲧⲟⲓ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲧⲉⲥⲁⲫⲉ ⳿ⲙⲓ̅ⲃ̅ ⳿ⲛⲥⲓⲟⲩ.
2 Ó sì lóyún, ó sì kígbe ni ìrọbí, ó sì wà ni ìrora àti bímọ.
ⲃ̅ⲟⲩⲟϩ ⲉⲥ⳿ⲙⲃⲟⲕⲓ ⲉⲥⲱϣ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲉⲥϯ ⲛⲁⲕϩⲓ ⲉⲥⲙⲟⲕϩ ⲉⲥⲛⲁⲙⲓⲥⲓ.
3 Àmì mìíràn sì hàn ní ọ̀run; sì kíyèsi i, dragoni pupa ńlá kan, tí ó ní orí méje àti ìwo mẹ́wàá, àti adé méje ní orí rẹ̀.
ⲅ̅ⲟⲩⲟϩ ⲕⲉⲙⲏⲓⲛⲓ ⲁϥⲟⲩⲟⲛϩϥ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ⲟⲩⲟϩ ⲓⲥ ⲟⲩ⳿ⲇⲣⲁⲕⲱⲛ ⳿ⲛⲁⲟⲩⲁⲛ ⳿ⲛ⳿ⲭⲣⲱⲙ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⲡⲉ ⳿ⲉⲙⲁϣⲱ ⳿ⲉⲟⲩⲟⲛ ⲍ̅ ⳿ⲛ⳿ⲁⲫⲉ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⲛⲉⲙ ⲓ̅ ⳿ⲛⲧⲁⲡ ⳿ⲉⲟⲩⲟⲛ ⲍ̅ ⳿ⲛ⳿ⲭⲗⲟⲙ ϩⲓϫⲉⲛ ⲛⲉϥ⳿ⲁⲫⲏⲟⲩ⳿ⲓ.
4 Ìrù rẹ̀ sì wọ́ ìdámẹ́ta àwọn ìràwọ̀ ní ojú ọ̀run, ó sì jù wọ́n sí ilẹ̀ ayé, dragoni náà sì dúró níwájú obìnrin náà tí ó fẹ́ bímọ, pé nígbà tí o bá bí i, kí òun lè pa ọmọ rẹ̀ jẹ.
ⲇ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉϥⲥⲁⲧ ⲁϥⲱϣϯ ⳿ⲙⲫⲣⲉⲅ̅ ⳿ⲛⲛⲓⲥⲓⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉ ⳿ⲧⲫⲉ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥϩⲓⲧⲟⲩ ⳿ⲉⲡⲉⲥⲏⲧ ϩⲓϫⲉⲛ ⳿ⲡⲕⲁϩⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓ⳿ⲇⲣⲁⲕⲱⲛ ⲁϥⲟϩⲓ ⳿ⲉⲣⲁⲧϥ ⳿ⲙⲡⲉ⳿ⲙⲑⲟ ⳿ⲛϯ⳿ⲥϩⲓⲙⲓ ϩⲓⲛⲁ ⲉϣⲱⲡ ⲁⲥϣⲁⲛⲙⲓⲥⲓ ⳿ⲙⲡⲓϣⲏⲣⲓ ⳿ⲛⲧⲉϥⲟⲙⲕϥ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲓ⳿ⲇⲣⲁⲕⲱⲛ.
5 Ó sì bi ọmọkùnrin kan tí yóò fi ọ̀pá irin ṣe àkóso gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè, a sì gba ọmọ rẹ̀ lọ sókè sí ọ̀dọ̀ Ọlọ́run, àti sí orí ìtẹ́ rẹ̀.
ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲥⲙⲓⲥⲓ ⳿ⲙⲡⲓϣⲏⲣⲓ ⳿ⲛϩⲱⲟⲩⲧ ⲫⲁⲓ ⲡⲉ ⲫⲏⲉⲑⲛⲁ⳿ⲁⲙⲟⲛⲓ ⳿ⲛⲛⲓⲉⲑⲛⲟⲥ ϧⲉⲛ ⲟⲩ⳿ϣⲃⲱⲧ ⳿ⲙⲃⲉⲛⲓⲡⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩϩⲱⲗⲉⲙ ⳿ⲙⲡⲓϣⲏⲣⲓ ⳿ⲉ⳿ⲡϣⲱⲓ ϩⲁ ⲫϯ ⲛⲉⲙ ϩⲁ ⲡⲉϥ⳿ⲑⲣⲟⲛⲟⲥ.
6 Obìnrin náà sì sálọ sí aginjù, níbi tí a gbé ti pèsè ààyè sílẹ̀ dè é láti ọwọ́ Ọlọ́run wá, pé kí wọ́n máa bọ́ ọ níbẹ̀ ní ẹgbẹ̀fà ọjọ́ ó lé ọgọ́ta.
ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ϯ⳿ⲥϩⲓⲙⲓ ⲁⲥⲫⲱⲧ ⳿ⲉ⳿ⲡϣⲁϥⲉ ⳿ⲉⲡⲓⲙⲁ ⲉⲧⲁ ⲫϯ ⲥⲉⲃⲧⲱⲧϥ ⲛⲁⲥ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲥⲉϣⲁⲛⲟⲩϣⲥ ⳿ⲙⲙⲁⲩ ⳿ⲛⲟⲩϣⲟ ⲛⲉⲙ ⲥ̅ ⳿ⲛϥ̅ ⳿ⲛ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ.
7 Ogun sì ń bẹ ní ọ̀run: Mikaeli àti àwọn angẹli rẹ̀ bá dragoni náà jagun; dragoni sì jagun àti àwọn angẹli rẹ̀.
ⲍ̅ⲟⲩⲟϩ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲙⲃⲱⲧⲥ ⲁϥϣⲱⲡⲓ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ⲙⲓⲭⲁⲏⲗ ⲛⲉⲙ ⲛⲉϥⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⳿ⲉⲃⲱⲧⲥ ⲟⲩⲃⲉ ⲡⲓ⳿ⲇⲣⲁⲕⲱⲛ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓ⳿ⲇⲣⲁⲕⲱⲛ ⲁϥⲃⲱⲧⲥ ⲟⲩⲃⲏⲟⲩ ⲛⲉⲙ ⲛⲉϥⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ.
8 Wọ́n kò sì lè ṣẹ́gun; bẹ́ẹ̀ ni a kò sì rí ipò wọn mọ́ ni ọ̀run.
ⲏ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙⲡⲉϥ⳿ϣϫⲉⲙϫⲟⲙ ⲟⲩⲃⲏⲟⲩ ⳿ⲉϯ ⲛⲉⲙⲱⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲙⲡⲟⲩⲭⲁ ⲙⲁ ⲛⲁϥ ϫⲉ ⳿ⲉ⳿ⲡϣⲱⲓ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ.
9 A sì lé dragoni ńlá náà jáde, ejò láéláé nì, tí a ń pè ni Èṣù, àti Satani, tí ń tan gbogbo ayé jẹ: a sì lé e jù sí ilẹ̀ ayé, a sì lé àwọn angẹli rẹ̀ jáde pẹ̀lú rẹ̀.
ⲑ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩϩⲓⲟⲩ⳿ⲓ ⳿ⲙⲡⲓ⳿ⲇⲣⲁⲕⲱⲛ ⲡⲓⲛⲓϣϯ ⳿ⲛϩⲟϥ ⳿ⲡⲁⲣⲭⲉⲟⲥ ⲫⲏⲉⲧⲟⲩⲙⲟⲩϯ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⲡⲓⲇⲓ⳿ⲁⲃⲟⲗⲟⲥ ⳿ⲡⲥⲁⲧⲁⲛⲁⲥ ⲫⲏⲉⲧⲥⲱⲣⲉⲙ ⳿ⲙⲡⲓⲕⲟⲥⲙⲟⲥ ⲧⲏⲣϥ ⲁⲩϩⲓⲧϥ ⳿ⲉⲡⲉⲥⲏⲧ ⳿ⲙ⳿ⲡⲕⲁϩⲓ ⲁⲩϩⲓⲟⲩ⳿ⲓ ⳿ⲛⲛⲉϥⲕⲉⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⳿ⲉⲡⲉⲥⲏⲧ ⲛⲉⲙⲁϥ.
10 Mo sì gbọ́ ohùn ńlá ní ọ̀run, wí pè: “Nígbà yìí ni ìgbàlà dé, àti agbára, àti ìjọba Ọlọ́run wá, àti ọlá àti Kristi rẹ̀. Nítorí a tí le olùfisùn àwọn arákùnrin wa jáde, tí o ń fi wọ́n sùn níwájú Ọlọ́run wa lọ́sàn án àti lóru.
ⲓ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲉⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛ⳿ⲥⲙⲏ ⳿ⲙ⳿ⲡϣⲱⲓ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ⲉⲥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ϯⲛⲟⲩ ⲁ ⲡⲓⲟⲩϫⲁⲓ ϣⲱⲡⲓ ⲛⲉⲙ ϯϫⲟⲙ ⲛⲉⲙ ϯⲙⲉⲧⲟⲩⲣⲟ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲉⲛⲛⲟⲩϯ ⲛⲉⲙ ⲡⲓⲉⲣϣⲓϣⲓ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲉϥⲭ͞ⲣⲥ̅ ϫⲉ ⲁⲩϩⲓⲟⲩ⳿ⲓ ⳿ⲙⲡⲓⲕⲁⲧⲏⲅⲟⲣⲟⲥ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲉⲛ⳿ⲥⲛⲏⲟⲩ ⳿ⲉⲡⲓⲕⲁϩⲓ ⲫⲏⲉⲧⲁϥⲉⲣⲕⲁⲧⲏⲅⲟⲣⲓⲛ ⳿ⲙⲡⲉ⳿ⲙⲑⲟ ⳿ⲙⲫϯ ⳿ⲙⲡⲓ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⲛⲉⲙ ⲡⲓ⳿ⲉϫⲱⲣϩ.
11 Wọ́n sì ti ṣẹ́gun rẹ̀ nítorí ẹ̀jẹ̀ ọ̀dọ́-àgùntàn náà, àti nítorí ọ̀rọ̀ ẹ̀rí wọn, wọn kò sì fẹ́ràn ẹ̀mí wọn àní títí dé ikú.
ⲓ̅ⲁ̅ϫⲉ ⳿ⲛⲑⲱⲟⲩ ⲁⲩϭⲣⲟ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⲉⲑⲃⲉ ⳿ⲡ⳿ⲥⲛⲟϥ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲓϩⲓⲏⲃ ⲛⲉⲙ ⲉⲑⲃⲉ ⳿ⲡ⳿ⲥⲛⲟϥ ⳿ⲛⲧⲉ ⲧⲟⲩⲙⲉⲧⲙⲁⲣⲧⲩⲣⲟⲥ ϫⲉ ⲟⲩⲏⲓ ⲅⲁⲣ ⳿ⲙⲡⲟⲩⲙⲉⲛⲣⲉ ⲧⲟⲩⲯⲩⲭⲏ ϣⲁ ⳿ⲉ⳿ϧⲣⲏⲓ ⳿ⲉ⳿ⲫⲙⲟⲩ.
12 Nítorí náà ẹ máa yọ̀, ẹ̀yin ọ̀run, àti ẹ̀yin tí ń gbé inú wọn. Ègbé ni fún ayé àti Òkun; nítorí èṣù sọ̀kalẹ̀ tọ̀ yín wá ní ìbínú ńlá, nítorí ó mọ̀ pé ìgbà kúkúrú sá ni òun ní.”
ⲓ̅ⲃ̅ⲉⲑⲃⲉⲫⲁⲓ ⲟⲩⲛⲟϥ ⳿ⲙⲙⲱⲧⲉⲛ ⲛⲓⲫⲏⲟⲩ⳿ⲓ ⲛⲉⲙ ⲛⲏⲉⲧϣⲟⲡ ⳿ⲛϧⲏⲧⲟⲩ ⲟⲩⲟⲓ ⳿ⲙⲡⲓⲕⲁϩⲓ ⲛⲉⲙ ⳿ⲫⲓⲟⲙ ϫⲉ ⲁϥ⳿ⲓ ⲉⲡⲉⲥⲏⲧ ϩⲁⲣⲱⲧⲉⲛ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲓⲇⲓ⳿ⲁⲃⲟⲗⲟⲥ ⳿ⲉⲟⲩⲟⲛ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛ⳿ⲙⲃⲟⲛ ⳿ⲛϧⲏⲧϥ ⲉϥ⳿ⲉⲙⲓ ϫⲉ ⲕⲉⲕⲟⲩϫⲓ ⳿ⲛⲥⲏⲟⲩ ⲉⲧⲉ⳿ⲛⲧⲁϥ ⳿ⲙⲙⲁⲩ.
13 Nígbà tí dragoni náà rí pé a lé òun lọ sí ilẹ̀ ayé, ó ṣe inúnibíni sì obìnrin tí ó bí ọmọkùnrin náà.
ⲓ̅ⲅ̅ⲉⲧⲁϥⲛⲁⲩ ⲇⲉ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲓ⳿ⲇⲣⲁⲕⲱⲛ ϫⲉ ⲁⲩϩⲓⲧϥ ⳿ⲉ⳿ⲡⲕⲁϩⲓ ⲁϥϭⲟϫⲓ ⳿ⲛⲥⲁ ϯ⳿ⲥϩⲓⲙⲓ ⲑⲏ ⲉⲧⲁⲥⲙⲓⲥⲓ ⳿ⲙⲡⲓϣⲏⲣⲓ ⳿ⲛϩⲱⲟⲩⲧ.
14 A sì fi apá ìyẹ́ méjì tí idì ńlá náà fún obìnrin náà, pé kí ó fò lọ sí aginjù, sí ipò rẹ̀, níbi tí a ó gbe bọ ọ fún àkókò kan àti fún àwọn àkókò, àti fún ìdajì àkókò kúrò lọ́dọ̀ ejò náà.
ⲓ̅ⲇ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩϯ ⲛⲁⲥ ⳿ⲛⲛⲓϣϯ ⳿ⲛⲧⲉⲛϩ ⲃ̅ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛⲛⲁ ⲟⲩⲁϧⲱⲙ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲉⲥϩⲱⲗ ⳿ⲉ⳿ⲡϣⲁϥⲉ ⳿ⲛϫⲉ ϯ⳿ⲥϩⲓⲙⲓ ⳿ⲉ⳿ⲫⲙⲁ ⲉⲧⲟⲩⲛⲁϣⲁⲛⲟⲩϣⲥ ⳿ⲛⲟⲩⲥⲏⲟⲩ ⲛⲉⲙ ϩⲁⲛⲥⲏⲟⲩ ⲛⲉⲙ ⳿ⲧⲫⲁϣⲓ ⳿ⲛⲧⲉ ⲟⲩⲥⲏⲟⲩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲁ ⳿ⲡϩⲟ ⳿ⲙⲡⲓϩⲟϥ.
15 Ejò náà sì tu omi jáde láti ẹnu rẹ̀ wá bí odò ńlá sẹ́yìn obìnrin náà, kí ó lè fi ìṣàn omi náà gbà á lọ.
ⲓ̅ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓϩⲟϥ ⲁϥϩⲓⲟⲩ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲣⲱϥ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛⲟⲩⲓⲁⲣⲟ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ⲥⲁⲫⲁϩⲟⲩ ⳿ⲛϯ⳿ⲥϩⲓⲙⲓ.
16 Ilẹ̀ sì ran obìnrin náà lọ́wọ́, ilẹ̀ sì ya ẹnu rẹ̀, ó sì fi ìṣàn omi náà mú, tí dragoni náà tu jáde láti ẹnu rẹ̀ wá.
ⲓ̅ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲡⲕⲁϩⲓ ⲁϥⲟⲩⲱⲛ ⳿ⲛⲣⲱϥ ⲁϥⲟⲙⲕ ⳿ⲙⲡⲓⲓⲁⲣⲟ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ⲉⲧⲁ ⲡⲓ⳿ⲇⲣⲁⲕⲱⲛ ϩⲓⲧϥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲓⲫⲁϩⲟⲩ ⳿ⲛϯ⳿ⲥϩⲓⲙⲓ.
17 Dragoni náà sì bínú gidigidi sí obìnrin náà, ó sì lọ bá àwọn irú-ọmọ rẹ̀ ìyókù jagun, tí wọ́n ń pa òfin Ọlọ́run mọ̀, tí wọn sì di ẹ̀rí Jesu mú, Ó sì dúró lórí iyanrìn Òkun.
ⲓ̅ⲍ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁϥϫⲱⲛⲧ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲓ⳿ⲇⲣⲁⲕⲱⲛ ϩⲓϫⲉⲛ ϯ⳿ⲥϩⲓⲙⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥϣⲉ ⲛⲁϥ ⳿ⲉ⳿ⲓⲣⲓ ⳿ⲛⲟⲩⲃⲱⲧⲥ ⲛⲉⲙ ⳿ⲡⲥⲉⲡⲓ ⳿ⲙ⳿ⲡ⳿ⲥⲡⲉⲣⲙⲁ ⳿ⲛϯ⳿ⲥϩⲓⲙⲓ ⲛⲏⲉⲧⲁⲣⲉϩ ⳿ⲉⲛⲓⲉⲛⲧⲟⲗⲏ ⳿ⲛⲧⲉ ⲫϯ ⲛⲉⲙ ϯⲙⲉⲧⲙⲉⲑⲣⲉ ⳿ⲛⲧⲉ Ⲓⲏ̅ⲥ̅

< Revelation 12 >