< Revelation 12 >

1 Àmì ńlá kan sì hàn ni ọ̀run; obìnrin kan tí a fi oòrùn wọ̀ ní aṣọ, òṣùpá sì ń bẹ lábẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀, adé oníràwọ̀ méjìlá sì ń bẹ lórí rẹ̀.
Maniyere il eenonat adits milikito darotse b́be'eyi, aaw tahdek'tsú, aashitsu btufoniyere dash geddek'ts, tatse git k'eenwotsi jip'ets akliliyo btookats gúúfdek'ts, mááts iku b́be'eyi.
2 Ó sì lóyún, ó sì kígbe ni ìrọbí, ó sì wà ni ìrora àti bímọ.
Biwere na'i maac'i bteshi, shuwoshowere na'i shambo b́waare kic'at bkuhefere btesh.
3 Àmì mìíràn sì hàn ní ọ̀run; sì kíyèsi i, dragoni pupa ńlá kan, tí ó ní orí méje àti ìwo mẹ́wàá, àti adé méje ní orí rẹ̀.
Andoor k'osh milikito darotse b́be'eyi, shawat tookwotsnat tats k'aluwotsi detsts een bir daruwo b́be'eyi, b́tookatsnowere shawat zewdiwotsi gúfdek'tni b́tesh,
4 Ìrù rẹ̀ sì wọ́ ìdámẹ́ta àwọn ìràwọ̀ ní ojú ọ̀run, ó sì jù wọ́n sí ilẹ̀ ayé, dragoni náà sì dúró níwájú obìnrin náà tí ó fẹ́ bímọ, pé nígbà tí o bá bí i, kí òun lè pa ọmọ rẹ̀ jẹ.
b́ dúshoon k'eenwotsitsi keez kisho darotse geetsdek't datsats fet'b́k'ri, máátsman bshuwor bna'o k'oot'osh gawk'raat daruman shuwosh etiru máátsu shinatse need'b́wutsi,
5 Ó sì bi ọmọkùnrin kan tí yóò fi ọ̀pá irin ṣe àkóso gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè, a sì gba ọmọ rẹ̀ lọ sókè sí ọ̀dọ̀ Ọlọ́run, àti sí orí ìtẹ́ rẹ̀.
máátsunwere ash jamo birri gumbon keewit nungush na'o shuubk'ri, bnaaynmó Ik'o naashi jooro maants zafdek'eyi,
6 Obìnrin náà sì sálọ sí aginjù, níbi tí a gbé ti pèsè ààyè sílẹ̀ dè é láti ọwọ́ Ọlọ́run wá, pé kí wọ́n máa bọ́ ọ níbẹ̀ ní ẹgbẹ̀fà ọjọ́ ó lé ọgọ́ta.
máátsunwere woruwo maants áásho k'az bwos'i, manoke ik kume git balonat shiits aawosh it'ide'er detson bkoteet beyoko Ik'o bish manoke k'anitniye b́teshi.
7 Ogun sì ń bẹ ní ọ̀run: Mikaeli àti àwọn angẹli rẹ̀ bá dragoni náà jagun; dragoni sì jagun àti àwọn angẹli rẹ̀.
Darotse kes'o tuub́wtsi, Mika'elnat b́ melakiwotsn daruwonton bokeec'eyi, darwonat b́ melakiwotsowere aaniyidek't bokaari.
8 Wọ́n kò sì lè ṣẹ́gun; bẹ́ẹ̀ ni a kò sì rí ipò wọn mọ́ ni ọ̀run.
Ernmó daruwonat b́melakiyon da'eniye bowtsi, maniyere okonowere boosh darotse beyoko daatseratse.
9 A sì lé dragoni ńlá náà jáde, ejò láéláé nì, tí a ń pè ni Èṣù, àti Satani, tí ń tan gbogbo ayé jẹ: a sì lé e jù sí ilẹ̀ ayé, a sì lé àwọn angẹli rẹ̀ jáde pẹ̀lú rẹ̀.
Daruw eenonwere dash datsats shap'k'reyi, bí dats jamu darituwo Diyablosi wee Shed'ana err s'eegef shints dawunzoniye. Bí datsats b́juweyi, b́melakiwotswere bínton bojuweyi.
10 Mo sì gbọ́ ohùn ńlá ní ọ̀run, wí pè: “Nígbà yìí ni ìgbàlà dé, àti agbára, àti ìjọba Ọlọ́run wá, àti ọlá àti Kristi rẹ̀. Nítorí a tí le olùfisùn àwọn arákùnrin wa jáde, tí o ń fi wọ́n sùn níwájú Ọlọ́run wa lọ́sàn án àti lóru.
Maniyere il k'áári een iko darotse hank'o bíetfere tshishi, «Eshe and Ik'o kashiyo, b́kup'onat b́mengston waare. Bíko Krstos alo waare! no eshuwotsi no Ik'o shinatse t'úwe aawo s'aamifets teshtso no eshuwotsi s'aamifo juwewtsere,
11 Wọ́n sì ti ṣẹ́gun rẹ̀ nítorí ẹ̀jẹ̀ ọ̀dọ́-àgùntàn náà, àti nítorí ọ̀rọ̀ ẹ̀rí wọn, wọn kò sì fẹ́ràn ẹ̀mí wọn àní títí dé ikú.
Boowere mereero s'atsonat bo gawuts gawatse tuutson bín da'adek'rne, bo kashosh bobút'erawo botoko k'irosh beshidek't imrne,
12 Nítorí náà ẹ máa yọ̀, ẹ̀yin ọ̀run, àti ẹ̀yin tí ń gbé inú wọn. Ègbé ni fún ayé àti Òkun; nítorí èṣù sọ̀kalẹ̀ tọ̀ yín wá ní ìbínú ńlá, nítorí ó mọ̀ pé ìgbà kúkúrú sá ni òun ní.”
Mansh daruwotsnat bogitsotse beyiru jamwots gene'úwore! múk' aawu s'uz bísh b́ oortsok'o b́dantsotse Diyablos fayi eenon it maants b́ oot'tsotse datsonat aats k'arwotssh indowe itsha!»
13 Nígbà tí dragoni náà rí pé a lé òun lọ sí ilẹ̀ ayé, ó ṣe inúnibíni sì obìnrin tí ó bí ọmọkùnrin náà.
Daruwonú datsats b́ juweetsok'o b́ bek'tsok'on nungush na'a shuuts máátsu b́ giishi,
14 A sì fi apá ìyẹ́ méjì tí idì ńlá náà fún obìnrin náà, pé kí ó fò lọ sí aginjù, sí ipò rẹ̀, níbi tí a ó gbe bọ ọ fún àkókò kan àti fún àwọn àkókò, àti fún ìdajì àkókò kúrò lọ́dọ̀ ejò náà.
máátsunwere worwotse bish k'aniyets beyokok biirr biametwok'o aaki bangok'o arts bang gitwotsi bish imk'reyi, manoknowere dawunzman shinatse wokaar keez natonat badosh sheengshdetson detseyat bkotefera bteshi.
15 Ejò náà sì tu omi jáde láti ẹnu rẹ̀ wá bí odò ńlá sẹ́yìn obìnrin náà, kí ó lè fi ìṣàn omi náà gbà á lọ.
Máátsu di'on bdek'etwok'owat dawunzman fokitsi aatsok'o bodts aatso b́noonotse s'ud dek't bshuuts weeron b́kuut'i.
16 Ilẹ̀ sì ran obìnrin náà lọ́wọ́, ilẹ̀ sì ya ẹnu rẹ̀, ó sì fi ìṣàn omi náà mú, tí dragoni náà tu jáde láti ẹnu rẹ̀ wá.
Ernmó datsu máátsmansh bgaatsi, bnononowere k'eshedek'at daruman b́noonotse b́s'udts foko ushbk'ri.
17 Dragoni náà sì bínú gidigidi sí obìnrin náà, ó sì lọ bá àwọn irú-ọmọ rẹ̀ ìyókù jagun, tí wọ́n ń pa òfin Ọlọ́run mọ̀, tí wọn sì di ẹ̀rí Jesu mú, Ó sì dúró lórí iyanrìn Òkun.
Daruwonú máátsu fayat bnaar oortswotsnton kec'ewosh bíami, boowere Ik' aluwotsi kotfwotsnat Iyesus jangosh amaneeyat gawirwotsiye.

< Revelation 12 >