< Revelation 11 >
1 A sì fi ìfèéfèé kan fún mi tí o dàbí ọ̀pá-ìwọ̀n: ẹnìkan sì wí pé, “Dìde, wọn tẹmpili Ọlọ́run, àti pẹpẹ, àti àwọn tí ń sìn nínú rẹ̀.
ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩϯ ⳿ⲛⲟⲩⲕⲁϣ ⳿ⲛⲛⲟⲩⲃ ⲛⲏⲓ ⲉϥⲟⲓ ⳿ⲛⲟⲩ⳿ϣⲃⲱⲧ ⲉⲩϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲛⲏⲓ ϫⲉ ⲧⲱⲛⲕ ϣⲓ ⳿ⲙⲡⲓⲉⲣⲫⲉⲓ ⳿ⲛⲧⲉ ⲫϯ ⲛⲉⲙ ⲡⲓⲙⲁ⳿ⲛⲉⲣϣⲱⲟⲩϣⲓ ⲛⲉⲙ ⲛⲏⲉⲧⲟⲩⲱϣⲧ ⳿ⲛϧⲏⲧϥ.
2 Sì fi àgbàlá tí ń bẹ lóde tẹmpili sílẹ̀, má sì ṣe wọ́n ọ́n; nítorí tí a fi fún àwọn aláìkọlà: ìlú mímọ́ náà ni wọn ó sì tẹ̀ mọ́lẹ̀ ní oṣù méjìlélógójì.
ⲃ̅ⲛⲉⲙ ϯⲁⲩⲗⲏ ⲉⲧⲥⲁⲃⲟⲗ ⳿ⲙⲡⲓⲉⲣⲫⲉⲓ ϩⲓⲧⲥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲙⲡⲉⲣϣⲓⲧⲥ ϫⲉ ⲁⲩⲧⲏⲓⲥ ⳿ⲛⲛⲓⲉⲑⲛⲟⲥ ⲛⲉⲙ ϯⲃⲁⲕⲓ ⲉⲑⲟⲩⲁⲃ ⲉⲩ⳿ⲉϩⲱⲙⲓ ⳿ⲛϧⲏⲧⲥ ⳿ⲛⲙ̅ⲃ̅ ⳿ⲛ⳿ⲁⲃⲟⲧ.
3 Èmi ó sì yọ̀ǹda fún àwọn ẹlẹ́rìí mi méjèèje, wọn ó sì sọtẹ́lẹ̀ fún ẹgbẹ̀fà ọjọ́ ó lé ọgọ́ta nínú aṣọ ọ̀fọ̀.”
ⲅ̅ⲟⲩⲟϩ ⲉⲓ⳿ⲉϯ ⳿ⲙⲡⲁⲙⲉⲑⲣⲉ ⲃ̅ ⲉⲩ⳿ⲉⲉⲣ⳿ⲡⲣⲟⲫⲏ ⲧⲉⲩⲓⲛ ⳿ⲛⲟⲩϣⲟ ⳿ⲛⲥ̅ ⲛⲉⲙ ⲝ̅ ⳿ⲛ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⳿ⲉⲟⲩⲟⲛ ϩⲁⲛⲥⲟⲕ ⲧⲟⲓ ϩⲓⲱⲧⲟⲩ.
4 Wọ̀nyí ni igi olifi méjì náà, àti ọ̀pá fìtílà méjì náà tí ń dúró níwájú Olúwa ayé.
ⲇ̅ⲑⲁⲓ ⲧⲉ ϯⲃⲱ ⳿ⲥⲛⲟⲩϯ ⳿ⲛϫⲱⲓⲧ ⲛⲉⲙ ϯⲗⲩⲭⲛⲓⲁ ⳿ⲥⲛⲟⲩϯ ⲉⲧⲭⲏ ⲉⲩⲟϩⲓ ⳿ⲉⲣⲁⲧⲟⲩ ⳿ⲙⲡⲉ⳿ⲙⲑⲟ ⳿ⲙⲠ⳪.
5 Bí ẹnikẹ́ni bá sì fẹ́ pa wọn lára, iná ó ti ẹnu wọn jáde, a sì pa àwọn ọ̀tá wọn run, báyìí ni a ó sì pa ẹnikẹ́ni tí ó ba ń fẹ́ pa wọn lára run.
ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⲫⲏⲉⲧⲟⲩⲟⲩⲁϣϥ ⳿ⲛⲑⲱⲟⲩ ⲉⲩ⳿ⲉⲁⲓϥ ⲟⲩ⳿ⲭⲣⲱⲙ ⲉϥ⳿ⲉ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲣⲱⲟⲩ ⲉϥ⳿ⲉⲟⲩⲱⲙ ⳿ⲛⲥⲁ ⲛⲟⲩϫⲁϫⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲫⲏⲉⲑⲟⲩⲱϣ ⳿ⲉⲉⲣⲁⲇⲓⲕⲓⲛ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ⲡⲁⲓⲣⲏϯ ⲥⲉⲛⲁϧⲟⲑⲃⲟⲩ.
6 Àwọn wọ̀nyí ni ó ni agbára láti sé ọ̀run, tí òjò kò fi lè rọ̀ ni ọjọ́ àsọtẹ́lẹ̀ wọn. Wọ́n sì ní agbára lórí omi láti sọ wọn di ẹ̀jẹ̀, àti láti fi onírúurú àjàkálẹ̀-ààrùn kọlu ayé, nígbàkígbà tí wọ́n bá fẹ́.
ⲋ̅ϫⲉ ⲟⲩⲟⲛⲧⲟⲩ ⲉⲣϣⲓϣⲓ ⳿ⲙⲙⲁⲩ ⳿ⲉ⳿ϣⲑⲁⲙ ⳿ⲛ⳿ⲧⲫⲉ ϩⲓⲛⲁ ⳿ⲛⲧⲉ⳿ϣⲧⲉⲙ ⲙⲟⲩ⳿ⲛϩⲱⲟⲩ ⳿ⲓ ⳿ⲉ⳿ϩⲣⲏⲓ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲡⲓⲕⲁϩⲓ ⳿ⲛⲛⲓ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⲧⲏⲣⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉ ⲧⲟⲩ⳿ⲡⲣⲟⲫⲏ ⲧⲓⲁ ⲟⲩⲟϩ ⲟⲩⲟⲛⲧⲟⲩ ⲉⲣϣⲓϣⲓ ⲣⲱ ⲟⲛ ϩⲓϫⲉⲛ ⲛⲓⲙⲱⲟⲩ ⲉⲑⲣⲟⲩⲫⲟⲛϩⲟⲩ ⳿ⲛⲥⲉⲉⲣ⳿ⲥⲛⲟϥ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉϣⲁⲣⲓ ⳿ⲉ⳿ⲡⲕⲁϩⲓ ϧⲉⲛ ⲉⲣϧⲟⲧ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲉⲧⲟⲩⲟⲩⲁϣϥ ⳿ⲛⲑⲱⲟⲩ.
7 Nígbà tí wọn bá sì ti parí ẹ̀rí wọn, ẹranko tí o ń tí inú ọ̀gbun gòkè wá yóò bá wọn jagun, yóò sì ṣẹ́gun wọn, yóò sì pa wọ́n. (Abyssos )
ⲍ̅ⲟⲩⲟϩ ⲉϣⲱⲡ ⲁⲩϣⲁⲛϫⲱⲕ ⳿ⲛϯⲙⲉⲧⲙⲉⲑⲣⲉ ⳿ⲛⲧⲉ ⲧⲟⲩ⳿ⲡⲣⲟⲫⲏⲧⲓⲁ ⲡⲓⲑⲏⲣⲓⲟⲛ ⲇⲉ ⲉⲑⲛⲏⲟⲩ ⳿ⲉ⳿ⲡϣⲱⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲫⲛⲟⲩⲛ ⲉϥ⳿ⲉ⳿ⲓⲣⲓ ⳿ⲛⲟⲩⲃⲱⲧⲥ ⲛⲉⲙⲱⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲉϥ⳿ⲉϭⲣⲟ ⳿ⲉⲣⲱⲟⲩ ⲉϥ⳿ⲉϧⲟⲑⲃⲟⲩ. (Abyssos )
8 Òkú wọn yóò sì wà ni ìgboro ìlú ńlá náà tí a ń pè ní Sodomu àti Ejibiti nípa ti ẹ̀mí, níbi tí a gbé kan Olúwa wọ́n mọ́ àgbélébùú.
ⲏ̅ⲟⲩⲟϩ ⲉⲣⲉ ⲡⲟⲩⲥⲱⲙⲁ ⲉϥ⳿ⲉϣⲱⲡⲓ ϩⲓ ⲡⲓ⳿ϣⲑⲏϩ ⳿ⲛⲧⲉ ϯⲛⲓϣϯ ⳿ⲙⲃⲁⲕⲓ ⲑⲏ ⲉⲧⲟⲩⲙⲟⲩϯ ⳿ⲉⲣⲟⲥ ⳿ⲙⲡ͞ⲛⲁ̅ⲧⲓⲕⲟⲥ ϫⲉ ⲥⲟⲇⲟⲙⲁ ⳿ⲛⲧⲉ ⲭⲏⲙⲓ ⲡⲓⲙⲁ ⲉⲧⲁⲩⲉϣ ⲡⲟⲩ⳪ ⳿ⲙⲙⲟϥ.
9 Fún ọjọ́ mẹ́ta àti ààbọ̀ ni àwọn ènìyàn nínú ènìyàn gbogbo àti ẹ̀yà, àti èdè, àti orílẹ̀, wo òkú wọn, wọn kò si jẹ kì a gbé òkú wọn sínú ibojì.
ⲑ̅ⲟⲩⲟϩ ⲉⲩ⳿ⲉⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲡⲟⲩⲥⲱⲙⲁ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲫⲩⲗⲏ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲛⲉⲙ ⲗⲁⲟⲥ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲛⲉⲙ ⲗⲁⲥ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲛⲉⲙ ⳿ϣⲗⲟⲗ ⲛⲓⲃⲉⲛ ⲉⲩ⳿ⲉϫⲟⲩϣⲧ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲛⲟⲩⲥⲱⲙⲁ ⳿ⲛⲅ̅ ⳿ⲛ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⲛⲉⲙ ⲟⲩⲫⲁϣⲓ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛⲛⲟⲩⲭⲁ ⳿ϩⲗⲓ ⳿ⲉⲭⲁ ⲛⲟⲩⲥⲱⲙⲁ ϧⲉⲛ ⲡⲓ⳿ⲙϩⲁⲩ.
10 Àti àwọn tí o ń gbé orí ilẹ̀ ayé yóò sì yọ̀ lé wọn lórí, wọn yóò sì ṣe àríyá, wọn ó sì ta ara wọn lọ́rẹ; nítorí tí àwọn wòlíì méjèèjì yìí dá àwọn tí o ń bẹ lórí ilẹ̀ ayé lóró.
ⲓ̅ⲟⲩⲟϩ ⲉⲩ⳿ⲉⲣⲁϣⲓ ⲧⲏⲣⲟⲩ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲏⲉⲧϣⲟⲡ ϩⲓϫⲉⲛ ⲡⲓⲕⲁϩⲓ ⳿ⲉ⳿ϩⲣⲏⲓ ⳿ⲉϫⲱⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲩ⳿ⲉⲟⲩⲛⲟϥ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲩ⳿ⲉⲟⲩⲱⲣⲡ ⳿ⲛϩⲁⲛⲇⲱⲣⲟⲛ ⳿ⲛⲛⲟⲩⲉⲣⲏⲟⲩ ⲉⲩϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⲛⲁⲓ ⲛⲉ ⲛⲓ⳿ⲡⲣⲟⲫⲏ ⲧⲏⲥ ⲃ̅ ⲛⲏⲉⲧⲁⲩⲉⲣⲃⲁⲥⲁⲛⲓⲍⲓⲛ ⳿ⲛⲛⲏⲉⲧϣⲟⲡ ϩⲓϫⲉⲛ ⲡⲓⲕⲁϩⲓ.
11 Àti lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta àti ààbọ̀ náà, ẹ̀mí ìyè láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá wọ inú wọn, wọn sì dìde dúró ni ẹsẹ̀ wọn; ẹ̀rù ńlá sì ba àwọn tí o rí wọn.
ⲓ̅ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ⲉⲥ⳿ⲉϣⲱⲡⲓ ⲙⲉⲛⲉⲛⲥⲁ ⲅ̅ ⳿ⲛ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⲛⲉⲙ ⲟⲩⲫⲁϣⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲟⲩⲡ͞ⲛⲁ̅ ⳿ⲛⲧⲉ ⲫϯ ⲉϥ⳿ⲉϣⲉ ⳿ⲉϧⲟⲩⲛ ⳿ⲉⲣⲱⲟⲩ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲩ⳿ⲉⲟϩⲓ ⳿ⲉⲣⲁⲧⲟⲩ ϩⲓϫⲉⲛ ⲛⲟⲩϭⲁⲗⲁⲩϫ ⲟⲩⲟϩ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛϩⲟϯ ⲉⲥ⳿ⲉ⳿ⲓ ⳿ⲉ⳿ϧⲣⲏⲓ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲛⲏ ⳿ⲉⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲣⲱⲟⲩ.
12 Wọn sì gbọ́ ohùn ńlá kan láti ọ̀run wá ń wí fún wọn pé, “Ẹ gòkè wá ìhín!” Wọn sì gòkè lọ sí ọ̀run nínú ìkùùkuu àwọsánmọ̀; lójú àwọn ọ̀tá wọn.
ⲓ̅ⲃ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲉⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛ⳿ⲥⲙⲏ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ⲉⲥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲛⲱⲟⲩ ϫⲉ ⲁⲙⲱⲓⲛⲓ ⳿ⲉ⳿ⲡϣⲱⲓ ⳿ⲉ⳿ⲙⲛⲁⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩϣⲉ ⲛⲱⲟⲩ ⳿ⲉ⳿ⲡϣⲱⲓ ⳿ⲉ⳿ⲧⲫⲉ ϧⲉⲛ ⲟⲩϭⲏⲡⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲩ⳿ⲉⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲣⲱⲟⲩ ⳿ⲛϫⲉ ⲛⲟⲩϫⲁϫⲓ.
13 Ní wákàtí náà omìmì-ilẹ̀ ńlá kan sì mì, ìdámẹ́wàá ìlú náà sì wó, àti nínú omìmì-ilẹ̀ náà ẹ̀ẹ́dẹ́gbàárin ènìyàn ní a pa; ẹ̀rù sì ba àwọn ìyókù, wọn sì fi ògo fún Ọlọ́run ọ̀run.
ⲓ̅ⲅ̅ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲛ⳿ϧⲣⲏⲓ ϧⲉⲛ ϯⲟⲩⲛⲟⲩ ⳿ⲉⲧⲉ⳿ⲙⲙⲁⲩ ⲉⲣⲉ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲙⲙⲟⲛⲙⲉⲛ ϣⲱⲡⲓ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲫⲣⲉⲅ̅ ⳿ⲛϯⲃⲁⲕⲓ ⲁϥϩⲉⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩⲙⲟⲩ ⳿ⲛ⳿ϧⲣⲏⲓ ϧⲉⲛ ⲡⲓⲙⲟⲛⲙⲉⲛ ⳿ⲛϫⲉ ⲍ̅ ⳿ⲛϣⲟ ⳿ⲛⲣⲁⲛ ⳿ⲛⲣⲱⲙⲓ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲡⲥⲉⲡⲓ ⲁⲩⲙⲟϩ ⳿ⲛϩⲟϯ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩϯⲱⲟⲩ ⳿ⲙⲫϯ ⳿ⲛⲧⲉ ⳿ⲧⲫⲉ.
14 Ègbé kejì kọjá; sì kíyèsi i, ègbé kẹta sì ń bọ̀ wá kánkán.
ⲓ̅ⲇ̅ⲡⲓⲟⲩⲟⲓ ⳿ⲙⲙⲁϩⲃ̅ ⲁϥⲥⲓⲛⲓ ⲟⲩⲟϩ ϩⲏⲡⲡⲉ ⲓⲥ ⲡⲓⲟⲩⲟⲓ ⳿ⲙⲙⲁϩⲅ̅ ⳿ϥⲛⲏⲟⲩ ⳿ⲛⲭⲱⲗⲉⲙ.
15 Angẹli keje sì fọn ìpè; a sì gbọ́ ohùn ńlá láti ọ̀run, wí pé, “Ìjọba ayé di ti Olúwa wá, àti tí Kristi rẹ̀; òun yóò sì jẹ ọba láé àti láéláé!” (aiōn )
ⲓ̅ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓⲙⲁϩⲍ̅ ⳿ⲛⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲁϥⲉⲣⲥⲁⲗⲡⲓⲍⲓⲛ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩϣⲱⲡⲓ ⳿ⲛϫⲉ ϩⲁⲛⲛⲓϣϯ ⳿ⲛ⳿ⲥⲙⲏ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ⲉⲩϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⳿ⲑⲙⲉⲧⲟⲩⲣⲟ ⳿ⲙⲡⲓⲕⲟⲥⲙⲟⲥ ⲁⲥϣⲱⲡⲓ ⳿ⲙⲠ⳪ ⲡⲉⲛⲛⲟⲩϯ ⲛⲉⲙ ⲡⲉϥⲭ͞ⲣⲥ̅ ⲟⲩⲟϩ ⲉϥ⳿ⲉⲉⲣⲟⲩⲣⲟ ϣⲁ ⲉⲛⲉϩ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲓⲉⲛⲉϩ. (aiōn )
16 Àwọn àgbà mẹ́rìnlélógún náà tí wọn jókòó níwájú Ọlọ́run lórí ìtẹ́ wọn, dojúbolẹ̀, wọn sì sin Ọlọ́run,
ⲓ̅ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ⲕ̅ⲇ̅ ⳿ⲙ⳿ⲡⲣⲉⲥⲃⲩⲧⲉⲣⲟⲥ ⲉⲧⲭⲏ ⳿ⲙⲡⲉ⳿ⲙⲑⲟ ⳿ⲙⲫϯ ⲉⲩϩⲉⲙⲥⲓ ϩⲓϫⲉⲛ ⲛⲓ⳿ⲑⲣⲟⲛⲟⲥ ⲁⲩϩⲓⲧⲟⲩ ⳿ⲉϫⲉⲛ ⲡⲟⲩϩⲟ ⲁⲩⲟⲩⲱϣⲧ ⳿ⲙⲫϯ.
17 wí pé: “Àwa fi ọpẹ́ fún ọ, Olúwa Ọlọ́run, Olódùmarè, tí ń bẹ, tí ó sì ti wà, nítorí pé ìwọ ti gba agbára ńlá rẹ̀, ìwọ sì ti jẹ ọba.
ⲓ̅ⲍ̅ⲉⲩϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⲧⲉⲛϣⲉⲡ⳿ϩⲙⲟⲧ ⳿ⲛⲧⲟⲧⲕ Ⲡ⳪ ⲫϯ ⲡⲓⲡⲁⲛⲧⲟⲕⲣⲁⲧⲱⲣ ⲫⲏⲉⲧϣⲟⲡ ⲟⲩⲟϩ ⲫⲏ ⲉⲛⲁϥϣⲟⲡ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲭⲛⲏⲟⲩ ϫⲉ ⲁⲕϭⲓ ⳿ⲛϯϫⲟⲙ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲕⲉⲣⲟⲩⲣⲟ.
18 Inú bí àwọn orílẹ̀-èdè, bẹ́ẹ̀ ni ìbínú rẹ̀ ti dé, àti àkókò láti dá àwọn òkú lẹ́jọ́, àti láti fi èrè fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ wòlíì, àti àwọn ènìyàn mímọ́, àti àwọn tí o bẹ̀rù orúkọ rẹ̀, àti ẹni kékeré àti ẹni ńlá; àti láti run àwọn tí ń pa ayé run.”
ⲓ̅ⲏ̅ⲟⲩⲟϩ ⲛⲓⲉⲑⲛⲟⲥ ⲁⲩϫⲱⲛⲧ ϫⲉ ⲁϥ⳿ⲓ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲉⲕϫⲱⲛⲧ ⲛⲉⲙ ⳿ⲡⲥⲏⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉ ϯ⳿ⲕⲣⲏⲥⲓⲥ ⳿ⲉϯϩⲁⲡ ⳿ⲉⲛⲓⲣⲉϥⲙⲱⲟⲩⲧ ⲟⲩⲟϩ ⳿ⲉϯ ⳿ⲙ⳿ⲫⲃⲉⲭⲉ ⳿ⲛⲧⲉ ⲛⲉⲕⲉⲃⲓⲁⲓⲕ ⲛⲱⲟⲩ ⲛⲓⲡⲣⲟⲫⲏⲧⲏⲥ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲁⲅⲓⲟⲥ ⲛⲉⲙ ⲛⲏ ⲧⲏⲣⲟⲩ ⲉⲧⲉⲣϩⲟϯ ϧⲁ⳿ⲧϩⲏ ⳿ⲙⲡⲉⲕⲣⲁⲛ ⲛⲓⲕⲟⲩϫⲓ ⲛⲉⲙ ⲛⲓⲛⲓϣϯ ⲉⲕ⳿ⲉⲧⲁⲕⲟ ⳿ⲛⲛⲏⲉⲧⲧⲁⲕⲟ ⳿ⲙⲡⲓⲕⲁϩⲓ.
19 A sì ṣí tẹmpili Ọlọ́run sílẹ̀ ní ọ̀run, a sì ri àpótí májẹ̀mú nínú tẹmpili rẹ̀. Mọ̀nàmọ́ná sì kọ, a sì gbọ́ ohùn, àrá sì sán, ilẹ̀ sì mi, yìnyín ńlá sì bọ́.
ⲓ̅ⲑ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁϥⲟⲩⲱⲛ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲓⲉⲣⲫⲉⲓ ⳿ⲛⲧⲉ ⲫϯ ⳿ⲛ⳿ϩⲣⲏⲓ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲥⲟⲩⲱⲛϩ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲛϫⲉ ϯⲕⲩⲃⲱⲧⲟⲥ ⳿ⲛⲧⲉ ϯⲇⲓ⳿ⲁⲑⲏⲕⲏ ϧⲉⲛ ⲡⲓⲉⲣⲫⲉⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲩϣⲱⲡⲓ ⳿ⲛϫⲉ ϩⲁⲛⲥⲉⲧⲉⲃⲣⲏϫ ⲛⲉⲙ ϩⲁⲛϧⲁⲣⲁⲃⲁⲓ ⲛⲉⲙ ϩⲁⲛ⳿ⲥⲙⲏ ⲛⲉⲙ ϩⲁⲛⲙⲟⲛⲙⲉⲛ ⲛⲉⲙ ϩⲁⲛⲁⲗ ⳿ⲙⲫⲉ