< Revelation 11 >

1 A sì fi ìfèéfèé kan fún mi tí o dàbí ọ̀pá-ìwọ̀n: ẹnìkan sì wí pé, “Dìde, wọn tẹmpili Ọlọ́run, àti pẹpẹ, àti àwọn tí ń sìn nínú rẹ̀.
Ba ban kwukwu giga ne du mi tindu niwu to kunkron u tsra kpe. Ba hla mu ndi, “Lu kri ndihi tsra hekali u Irji mba bagadi, mba biwa basi nzuhon nibre nimi.
2 Sì fi àgbàlá tí ń bẹ lóde tẹmpili sílẹ̀, má sì ṣe wọ́n ọ́n; nítorí tí a fi fún àwọn aláìkọlà: ìlú mímọ́ náà ni wọn ó sì tẹ̀ mọ́lẹ̀ ní oṣù méjìlélógójì.
Na tsra kahlan wa ahe ni kogon hekali na ba ban kima nu bikoraba. Ba chanzren ni tsatsra kikle gbua wu wha arbain-don-ha.
3 Èmi ó sì yọ̀ǹda fún àwọn ẹlẹ́rìí mi méjèèje, wọn ó sì sọtẹ́lẹ̀ fún ẹgbẹ̀fà ọjọ́ ó lé ọgọ́ta nínú aṣọ ọ̀fọ̀.”
Mi nu iha bi bla tsro nitumu nkon u bwu bla kpi-wuye-nishishi u vi 1,260, nimi nklon gwado.
4 Wọ̀nyí ni igi olifi méjì náà, àti ọ̀pá fìtílà méjì náà tí ń dúró níwájú Olúwa ayé.
Bi vu bla tsro-to biyi baba yi ba kunkron zaitun (olive) ha mba fitila ha wa ba kii ni shishi Baci u meme.
5 Bí ẹnikẹ́ni bá sì fẹ́ pa wọn lára, iná ó ti ẹnu wọn jáde, a sì pa àwọn ọ̀tá wọn run, báyìí ni a ó sì pa ẹnikẹ́ni tí ó ba ń fẹ́ pa wọn lára run.
Ndio ri nita ban ndi wawu ni kpaba timeme, ilu ni rhurhini nyumba nda ye gon bi kamba niba. inji wa nison tiba memea, a toki ba wuu ba.
6 Àwọn wọ̀nyí ni ó ni agbára láti sé ọ̀run, tí òjò kò fi lè rọ̀ ni ọjọ́ àsọtẹ́lẹ̀ wọn. Wọ́n sì ní agbára lórí omi láti sọ wọn di ẹ̀jẹ̀, àti láti fi onírúurú àjàkálẹ̀-ààrùn kọlu ayé, nígbàkígbà tí wọ́n bá fẹ́.
Bi vu bla tsro ba ba heni kpayme ni duba ka kla shulu nitu du lu na kulu ni vi biwa ba bwu no tsro ekpi bi koshishiba. Ba heni gbengblen u kma ba mmaba ti iyi nda wru meme ni aloba nkankan, batari son du he toki.
7 Nígbà tí wọn bá sì ti parí ẹ̀rí wọn, ẹranko tí o ń tí inú ọ̀gbun gòkè wá yóò bá wọn jagun, yóò sì ṣẹ́gun wọn, yóò sì pa wọ́n. (Abyssos g12)
Bata na bla kle tsro wu ye koshishi ba, meme ibrji wa a rhurhi ni hlo ba bana to nchi mana'a, a ni kru ni tunkon kikle gbua nda wuu ba. (Abyssos g12)
8 Òkú wọn yóò sì wà ni ìgboro ìlú ńlá náà tí a ń pè ní Sodomu àti Ejibiti nípa ti ẹ̀mí, níbi tí a gbé kan Olúwa wọ́n mọ́ àgbélébùú.
Ikbon mba ni kru ni tunkon kikle gbua (wa ba yoba ni sranro ndi Sodom mba Masar), bubu wa ba klo bachi wu nitu kunkron.
9 Fún ọjọ́ mẹ́ta àti ààbọ̀ ni àwọn ènìyàn nínú ènìyàn gbogbo àti ẹ̀yà, àti èdè, àti orílẹ̀, wo òkú wọn, wọn kò si jẹ kì a gbé òkú wọn sínú ibojì.
Nivi tra ni mbru bari rhini gbungblu inji, igrji, ilan, mba meme ba ya ikbon mba. Bana du ba vu ba sru ni ibe na.
10 Àti àwọn tí o ń gbé orí ilẹ̀ ayé yóò sì yọ̀ lé wọn lórí, wọn yóò sì ṣe àríyá, wọn ó sì ta ara wọn lọ́rẹ; nítorí tí àwọn wòlíì méjèèjì yìí dá àwọn tí o ń bẹ lórí ilẹ̀ ayé lóró.
Biwa ba kii ni meme ba takpe nitumba nda ti gan. ba tru kpiwu ngiri hi ni kpamba nitu anabawa hariba ba ti bi son ni memeba iya kpukpome.
11 Àti lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta àti ààbọ̀ náà, ẹ̀mí ìyè láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá wọ inú wọn, wọn sì dìde dúró ni ẹsẹ̀ wọn; ẹ̀rù ńlá sì ba àwọn tí o rí wọn.
Hu gon ise tra ni mbrua, ivri u kma ye sisren rhini Irjhi ani rinimimba, i ba lu kri ni za mba. kikle sisiri ni kuu nitu biwa ba too a.
12 Wọn sì gbọ́ ohùn ńlá kan láti ọ̀run wá ń wí fún wọn pé, “Ẹ gòkè wá ìhín!” Wọn sì gòkè lọ sí ọ̀run nínú ìkùùkuu àwọsánmọ̀; lójú àwọn ọ̀tá wọn.
Niki ba wo kikle ilan rhini shulu nitre ni ba ndi, “Hon ye niwa “i ba hon hini shulu nimi kla lu inda don bi kamba niba ba kri si ya.
13 Ní wákàtí náà omìmì-ilẹ̀ ńlá kan sì mì, ìdámẹ́wàá ìlú náà sì wó, àti nínú omìmì-ilẹ̀ náà ẹ̀ẹ́dẹ́gbàárin ènìyàn ní a pa; ẹ̀rù sì ba àwọn ìyókù, wọn sì fi ògo fún Ọlọ́run ọ̀run.
Ni nton kima, kikle igrjhu meme ni he, i ri-ni-mi-wlon wu gbua ni ziilhe. Igrjhumemea ni wuu inji duba tabgban, i biwa na nawoa ba kuukikle sisiri nda nzu irjhi u shulu hon ni gbegblen ma.
14 Ègbé kejì kọjá; sì kíyèsi i, ègbé kẹta sì ń bọ̀ wá kánkán.
Iyambi wu ha ka hiye. Ya! Iya u tra niye gbagbla.
15 Angẹli keje sì fọn ìpè; a sì gbọ́ ohùn ńlá láti ọ̀run, wí pé, “Ìjọba ayé di ti Olúwa wá, àti tí Kristi rẹ̀; òun yóò sì jẹ ọba láé àti láéláé!” (aiōn g165)
Niki meleka u tangban a fuu njon-gan ma, i kikle balan rhini shulu ba tre, “Ngbrankochu u gbugblu a kma ti ngbrakochu u Bachi mba u kristi ma wa ani son ni tu chumba se ni se. (aiōn g165)
16 Àwọn àgbà mẹ́rìnlélógún náà tí wọn jókòó níwájú Ọlọ́run lórí ìtẹ́ wọn, dojúbolẹ̀, wọn sì sin Ọlọ́run,
Niki, bi chiche shirin don ha ba, wa ba kii nitu ruron u nzu honba ni shishi irjhi, ba kulhe ni shishi mba nda nzu irji hon.
17 wí pé: “Àwa fi ọpẹ́ fún ọ, Olúwa Ọlọ́run, Olódùmarè, tí ń bẹ, tí ó sì ti wà, nítorí pé ìwọ ti gba agbára ńlá rẹ̀, ìwọ sì ti jẹ ọba.
Ba tre ndi, ki ngiri niwu, baci irjhi wa azan wawu, wandi a he, mba wawu wa ana he, nitu wu ban kikle gbengblen me ni ri ti mulki me. vunvu Greek bi zan bi u sen ba he ni nyu tre/ wandi ana he, mba wandi ahei/ i vunvuu bari wa ba ye ni kogon, u bi Greek ba ba ka nya ndi/ mba wandi ani yea./
18 Inú bí àwọn orílẹ̀-èdè, bẹ́ẹ̀ ni ìbínú rẹ̀ ti dé, àti àkókò láti dá àwọn òkú lẹ́jọ́, àti láti fi èrè fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ wòlíì, àti àwọn ènìyàn mímọ́, àti àwọn tí o bẹ̀rù orúkọ rẹ̀, àti ẹni kékeré àti ẹni ńlá; àti láti run àwọn tí ń pa ayé run.”
Gbungblu ba bana ti nfu i nfu me ngame a ye. nton a ye wa bi wandi ba kwu ye duba kpa gaatre mba, mba du wu nu lada ni mri bindu me baba anabawa ba, ni tsatsra inji bi irjhi, mba biwa ba ti sisiri ndeme, ni bi wa bana he tukpe na mba bi kikle ninkon nton ye ye ni du zi ihe, biwa ba zii meme lhe.
19 A sì ṣí tẹmpili Ọlọ́run sílẹ̀ ní ọ̀run, a sì ri àpótí májẹ̀mú nínú tẹmpili rẹ̀. Mọ̀nàmọ́ná sì kọ, a sì gbọ́ ohùn, àrá sì sán, ilẹ̀ sì mi, yìnyín ńlá sì bọ́.
Niki hekali Irjhi ni shulu a bwuu i bato sanduki u alkawali ma ni mi hekalia. Ba zran luzen jbu nkankan, wrukunzan, ni igrjumeme, mba kikle lunitita ba ye hu ti

< Revelation 11 >