< Revelation 10 >

1 Mó sì rí angẹli mìíràn alágbára ò ń ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ wá, a fi àwọsánmọ̀ wọ̀ ọ́ ni aṣọ; òṣùmàrè sì ń bẹ ní orí rẹ̀, ojú rẹ̀ sì dàbí oòrùn, àti ẹsẹ̀ rẹ̀ bí ọ̀wọ́n iná.
ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲕⲉⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲉϥϫⲟⲣ ⳿ⲉⲁϥ⳿ⲓ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ⳿ⲉⲟⲩⲟⲛ ⲟⲩϭⲏⲡⲓ ⲧⲟⲓ ϩⲓⲱⲧϥ ⲟⲩⲟϩ ϯ⳿ⲓⲣⲓⲥ ⲉⲥⲭⲏ ϩⲓϫⲉⲛ ⲧⲉϥⲁⲫⲉ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉϥϩⲟ ⲉϥⲟⲓ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏ ⲟⲩⲟϩ ⲛⲉϥϭⲁⲗⲁⲩϫ ⲉⲩⲟⲓ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛϩⲁⲛ⳿ⲥⲧⲩⲗⲗⲟⲥ ⳿ⲛ⳿ⲭⲣⲱⲙ.
2 Ó sì ní ìwé kékeré kan tí a ṣí ní ọwọ́ rẹ̀; ó sì fi ẹsẹ̀ rẹ̀ ọ̀tún lé Òkun, àti ẹsẹ̀ rẹ̀ òsì lé ilẹ̀.
ⲃ̅ⲟⲩⲟϩ ⲟⲩⲟⲛ ⲟⲩϫⲱⲙ ⳿ⲛ⳿ϧⲣⲏⲓ ϧⲉⲛ ⲧⲉϥϫⲓϫ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥⲭⲱ ⳿ⲛⲧⲉϥϭⲁⲗⲟϫ ⳿ⲛⲟⲩ⳿ⲓⲛⲁⲙ ϩⲓϫⲉⲛ ⳿ⲫⲓⲟⲙ ⲧⲉϥϫⲁϭⲏ ϩⲓϫⲉⲛ ⲡⲓⲕⲁϩⲓ.
3 Ó sì ké lóhùn rara, bí ìgbà tí kìnnìún bá bú ramúramù. Nígbà tí ó sì ké, àwọn àrá méje náà fọhùn.
ⲅ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁϥⲱϣ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⲟⲩⲛⲓϣϯ ⳿ⲛ⳿ⲥⲙⲏ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛⲟⲩⲙⲟⲩ⳿ⲓ ⲉϥϩⲉⲙϩⲉⲙ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲧⲁϥⲱϣ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⲁ ϯⲍ̅ ⳿ⲛϧⲁⲣⲁⲃⲁⲓ ⲁⲩϯ ⳿ⲛⲧⲟⲩ⳿ⲥⲙⲏ.
4 Nígbà tí àwọn àrá méje fọhùn, mo múra àti kọ̀wé, mo sì gbọ́ ohùn láti ọ̀run wá ń wí fún pé, “Fi èdìdì di ohun tí àwọn àrá méje náà sọ, má sì ṣe kọ wọ́n sílẹ̀.”
ⲇ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲉⲛⲏⲉⲧⲁⲩϫⲟⲧⲟⲩ ⳿ⲛϫⲉ ϯⲍ̅ ⳿ⲛϧⲁⲣⲁⲃⲁⲓ ⲛⲁⲓⲛⲁ⳿ⲥϧⲏⲧⲟⲩ ⲟⲛ ⲡⲉ ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓⲥⲱⲧⲉⲙ ⳿ⲉⲟⲩ⳿ⲥⲙⲏ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ⲉⲥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ⲛⲏⲓ ϫⲉ ⲧⲟⲃⲟⲩ ⳿ⲙⲡⲉⲣ⳿ⲥϧⲉ ⲛⲏⲉⲧⲁⲩⲥⲁϫⲓ ⳿ⲙⲙⲱⲟⲩ ⳿ⲛϫⲉ ϯⲍ̅ ⳿ⲛϧⲁⲣⲁⲃⲁⲓ.
5 Angẹli náà tí mo rí tí ó dúró lórí Òkun àti lórí ilẹ̀, sì gbé ọwọ́ rẹ̀ sí òkè ọ̀run.
ⲉ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲓⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲉⲧⲁⲓⲛⲁⲩ ⳿ⲉⲣⲟϥ ⲉϥⲟϩⲓ ⳿ⲉⲣⲁⲧϥ ϩⲓϫⲉⲛ ⳿ⲫⲓⲟⲙ ⲛⲉⲙ ϩⲓϫⲉⲛ ⲡⲓⲕⲁϩⲓ ⲁϥⲥⲱⲟⲩⲧⲉⲛ ⳿ⲛⲧⲉϥⲟⲩ⳿ⲓⲛⲁⲙ ⳿ⲉ⳿ⲡϣⲱⲓ ⳿ⲉ⳿ⲧⲫⲉ.
6 Ó sì fi ẹni tí ń bẹ láààyè láé àti láé búra, ẹni tí o dá ọ̀run, àti ohun tí ń bẹ nínú rẹ̀, ayé ohun tí ń bẹ nínú rẹ̀ pé, “Kí yóò si ìjáfara mọ́. (aiōn g165)
ⲋ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁϥⲱⲣⲕ ⳿ⲙⲫⲏⲉⲧⲟⲛϧ ϣⲁ ⲉⲛⲉϩ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲓⲉⲛⲉϩ ⲫⲏⲉⲧⲁϥⲥⲱⲛⲧ ⳿ⲛ⳿ⲧⲫⲉ ⲛⲉⲙ ⲡⲓⲕⲁϩⲓ ⲛⲉⲙ ⳿ⲫⲓⲟⲙ ⲛⲉⲙ ⲛⲏⲉⲧϣⲟⲡ ⲧⲏⲣⲟⲩ ϫⲉ ⳿ⲛⲛⲉ ⳿ⲥⲛⲟⲩ ϣⲱⲡⲓ ϫⲉ. (aiōn g165)
7 Ṣùgbọ́n ní ọjọ́ ohùn angẹli keje, nígbà tí yóò ba fún ìpè, nígbà náà ni ohun ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run, gẹ́gẹ́ bí o tí sọ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, àwọn wòlíì ni a ó mú ṣẹ.”
ⲍ̅ϧⲉⲛ ⲡⲓ⳿ⲉϩⲟⲟⲩ ⳿ⲛⲧⲉ ϯ⳿ⲥⲙⲏ ⳿ⲛⲧⲉ ⲡⲓⲙⲁϩⲍ̅ ⳿ⲛⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲁϥϣⲁⲛⲉⲣⲥⲁⲗⲡⲓⲍⲓⲛ ⲁϥϫⲱⲕ ⲅⲁⲣ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ⳿ⲛϫⲉ ⲡⲓⲙⲩⲥⲧⲏⲣⲓⲟⲛ ⳿ⲛⲧⲉ ⲫϯ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⲉⲧⲁϥϩⲓⲱⲓϣ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϩⲓⲧⲉⲛ ⲛⲉϥⲉⲃⲓⲁⲓⲕ ⲛⲓⲡⲣⲟⲫⲏⲧⲏⲥ.
8 Ohùn náà tí mo gbọ́ láti ọ̀run tún ń ba mi sọ̀rọ̀, ó sì wí pé, “Lọ, gba ìwé tí o ṣí lọ́wọ́ angẹli tí o dúró lórí Òkun àti lórí ilẹ̀.”
ⲏ̅ⲟⲩⲟϩ ϯ⳿ⲥⲙⲏ ⲉⲧⲁⲓⲥⲟⲑⲙⲉⲥ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲧⲫⲉ ⲛⲁⲥⲥⲁϫⲓ ⲛⲉⲙⲏⲓ ⲡⲉ ⲉⲥϫⲱ ⳿ⲙⲙⲟⲥ ϫⲉ ⲙⲁϣⲉ ⲛⲁⲕ ϭⲓ ⳿ⲙⲡⲓϫⲱⲙ ⲉⲑⲟⲩⲏⲛ ⲫⲏⲉⲧϧⲉⲛ ⳿ⲧϫⲓϫ ⳿ⲙⲡⲓⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲫⲏⲉⲧⲟϩⲓ ⳿ⲉⲣⲁⲧϥ ϩⲓϫⲉⲛ ⳿ⲫⲓⲟⲙ ⲛⲉⲙ ϩⲓϫⲉⲛ ⲡⲓⲕⲁϩⲓ.
9 Mo sì tọ angẹli náà lọ, mo sì wí fún pé, “Fún mi ní ìwé kékeré náà.” Ó sì wí fún mi pé, “Gbà kí o sì jẹ ẹ́ tan: yóò dàbí oyin.”
ⲑ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓϣⲉ ⲛⲏⲓ ϩⲁ ⲡⲓⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲡⲉϫⲏⲓ ⲛⲁϥ ϫⲉ ⲙⲁ ⲡⲓϫⲱⲙ ⲛⲏⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉϫⲁϥ ⲛⲏⲓ ϫⲉ ϭⲓⲧϥ ⲛⲁⲕ ⲟⲩⲟϩ ⲉϥ⳿ⲉ⳿ⲑⲣⲉ ⲧⲉⲕⲛⲉϫⲓ ⲉⲣϣⲁϣⲓ ⲟⲩⲟϩ ⲉϥ⳿ⲉϣⲱⲡⲓ ⲉϥϩⲟⲗϫ ϧⲉⲛ ⲣⲱⲕ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛⲟⲩⲉⲃⲓⲱ.
10 Mo sì gba ìwé kékeré náà ni ọwọ́ angẹli náà mo sì jẹ ẹ́ tan; ó sì dùn lẹ́nu mi bí oyin; bí mo sì tí jẹ ẹ́ tan, inú mi korò.
ⲓ̅ⲟⲩⲟϩ ⲁⲓϭⲓ ⳿ⲙⲡⲓϫⲱⲙ ⳿ⲉⲃⲟⲗ ϧⲉⲛ ⳿ⲧϫⲓϫ ⳿ⲙⲡⲓⲁⲅⲅⲉⲗⲟⲥ ⲟⲩⲟϩ ⲁϥϣⲱⲡⲓ ⲉϥϩⲟⲗϫ ϧⲉⲛ ⲣⲱⲓ ⳿ⲙ⳿ⲫⲣⲏϯ ⳿ⲛⲟⲩ⳿ⲉⲃⲓⲱ ⲟⲩⲟϩ ⲉⲧⲁⲓⲟⲩⲟⲙϥ ⲁ ⲧⲁⲛⲉϫⲓ ⲉⲣϣⲁϣⲓ.
11 A sì wí fún mi pé, “Ìwọ ó sì tún sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, àti orílẹ̀ àti èdè, àti àwọn ọba.”
ⲓ̅ⲁ̅ⲟⲩⲟϩ ⲡⲉϫⲱⲟⲩ ⲛⲏⲓ ϫⲉ ϩⲱϯ ⳿ⲉⲣⲟⲕ ⲟⲛ ⲡⲉ ⳿ⲛⲧⲉⲕⲉⲣ⳿ⲡⲣⲟⲫⲏⲧⲉⲩⲓⲛ ⳿ⲉϫⲉⲛ ϩⲁⲛⲗⲁⲟⲥ ⲛⲉⲙ ϩⲁⲛ⳿ϣⲗⲟⲗ ⲛⲉⲙ ϩⲁⲛⲗⲁⲥ ⲛⲉⲙ ⲟⲩⲙⲏϣ ⳿ⲛⲟⲩⲣⲟ

< Revelation 10 >