< Psalms 95 >

1 Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a kọ orin ayọ̀ sí Olúwa, ẹ jẹ́ kí a kígbe sókè sí àpáta ìgbàlà wa.
Antao hisabo am’ Iehovà; Antao hipoña-peo amy lamilamim-pandrombahan-tikañey.
2 Ẹ jẹ́ kí a wá sí iwájú rẹ̀ pẹ̀lú ọpẹ́ kí a sì pòkìkí rẹ̀ pẹ̀lú ohun èlò orin àti ìyìn.
Ntao hiatrek’Aze am-pañandriañañe, antao hirebek’ ama’e an-tsabo.
3 Nítorí Olúwa Ọlọ́run títóbi ni, ọba tí ó tóbi ju gbogbo òrìṣà lọ.
Andrianamboatse jabahinake t’Iehovà, naho Mpanjaka ra’elahy ambone’ ze fanalolahy iaby.
4 Ní ọwọ́ rẹ̀ ni ọ̀gbun ilẹ̀ wà, ṣóńṣó orí òkè tirẹ̀ ní ṣe.
Am-pità’e ao o hatsikeokeo’ ty tane toio, Aze ka o lengom-bohitseo.
5 Tirẹ̀ ni Òkun, nítorí òun ni ó dá a àti ọwọ́ rẹ̀ ni ó fi dá ìyàngbẹ ilẹ̀.
Aze i riakey, ie ty namboatse aze, nitsenèm-pità’e i tane maikey.
6 Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a foríbalẹ̀ kí a sìn ín, ẹ jẹ́ kí a kúnlẹ̀ níwájú Olúwa ẹni tí ó dá wa,
Mb’etoa, hiambane vaho hitalaho, antao hanongalek’ añatrefa’ Iehovà Mpitsene antikañe.
7 nítorí òun ni Ọlọ́run wa, àwa sì ni ènìyàn pápá rẹ̀, àti ọ̀wọ́ ẹran ni abẹ́ ìpamọ́ rẹ̀. Lónìí tí ìwọ bá gbọ́ ohùn rẹ̀,
Amy te ie t’i Andrianañaharentikañe; itika ro ondatim-piandraza’e, naho ty lia-raim-pità’e; Anito, naho janjiñe’ areo i fiarañanaña’ey!
8 “Ẹ má ṣe sé ọkàn yín le gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ṣe ní Meriba, àti bí ẹ ti ṣe ní ọjọ́ náà ní Massa ní aginjù,
Ko mañagàñe arofo, manahake te Meriba añe, tañ’andro’ i Masa am-babangoañ’ añe;
9 nígbà tí àwọn baba yín dán mi wò tí wọn wádìí mi, tí wọn sì rí iṣẹ́ mi.
Ie nazizin-droae’ areo, naoveove’iareo ndra te nioni’iereo o fitoloñakoo.
10 Fún ogójì ọdún ni èmi fi bínú sí ìran náà; mo wí pé, ‘Wọ́n jẹ́ ènìyàn tí ọkàn wọn ṣáko lọ wọn kò sì mọ ọ̀nà mi.’
Efa-polo taoñe te nalaiñeko i tariratsey le nanoeko ty hoe: foko miola an-troke, fa tsy apota’ iareo o satakoo;
11 Nítorí náà ni mo kéde ìbúra nínú ìbínú mi, ‘Wọn kì yóò wọ ibi ìsinmi mi.’”
Aa le nifanta ami’ty fifomboko: Toe tsy himoaha’iareo ty fitofàko.

< Psalms 95 >