< Psalms 95 >
1 Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a kọ orin ayọ̀ sí Olúwa, ẹ jẹ́ kí a kígbe sókè sí àpáta ìgbàlà wa.
O fahsru, lela kut in kaksakin LEUM GOD, Lela kut in on ke engan nu sin God su langoekut.
2 Ẹ jẹ́ kí a wá sí iwájú rẹ̀ pẹ̀lú ọpẹ́ kí a sì pòkìkí rẹ̀ pẹ̀lú ohun èlò orin àti ìyìn.
Lela kut in tuku nu ye mutal ke kulo, Ac yuk on in engan ke kaksak.
3 Nítorí Olúwa Ọlọ́run títóbi ni, ọba tí ó tóbi ju gbogbo òrìṣà lọ.
Tuh LEUM GOD El sie God ku, El sie tokosra kulana fin god nukewa.
4 Ní ọwọ́ rẹ̀ ni ọ̀gbun ilẹ̀ wà, ṣóńṣó orí òkè tirẹ̀ ní ṣe.
El Leum fin faclu nufon, Liki yen loal in luf uh nu yen fulat in eol uh.
5 Tirẹ̀ ni Òkun, nítorí òun ni ó dá a àti ọwọ́ rẹ̀ ni ó fi dá ìyàngbẹ ilẹ̀.
El Leum fin meoa, su El orala, Oayapa faclu su El lumahla.
6 Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a foríbalẹ̀ kí a sìn ín, ẹ jẹ́ kí a kúnlẹ̀ níwájú Olúwa ẹni tí ó dá wa,
Fahsru, lela kut in epasr ac alu nu sel, Lela kut in sikukmutunte ye mutun LEUM GOD, su orekutla!
7 nítorí òun ni Ọlọ́run wa, àwa sì ni ènìyàn pápá rẹ̀, àti ọ̀wọ́ ẹran ni abẹ́ ìpamọ́ rẹ̀. Lónìí tí ìwọ bá gbọ́ ohùn rẹ̀,
Tuh El God lasr, Ac kut mwet su El nunku kac, Ac un sheep natul su El karingin. Misenge, porongo ma El fahk:
8 “Ẹ má ṣe sé ọkàn yín le gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ṣe ní Meriba, àti bí ẹ ti ṣe ní ọjọ́ náà ní Massa ní aginjù,
“Nik kowos srangesr lohng kas, oana mwet matu lowos ke elos muta in Meribah, Oana ke len se elos muta yen mwesis Massah.
9 nígbà tí àwọn baba yín dán mi wò tí wọn wádìí mi, tí wọn sì rí iṣẹ́ mi.
Elos tuh srikeyu we, Elos ne liye ma nga oru nu selos.
10 Fún ogójì ọdún ni èmi fi bínú sí ìran náà; mo wí pé, ‘Wọ́n jẹ́ ènìyàn tí ọkàn wọn ṣáko lọ wọn kò sì mọ ọ̀nà mi.’
Nga tuh arulana toasr selos yac angngaul, Ac nga fahk, ‘Mwet inge arulana likkeke! Elos tia lungse in akos ma sap luk.’
11 Nítorí náà ni mo kéde ìbúra nínú ìbínú mi, ‘Wọn kì yóò wọ ibi ìsinmi mi.’”
Nga tuh kasrkusrak ac orala wulela na ku se, fahk mu, ‘Kowos ac fah tiana ilyak nu in acn in mongla se Nga tuh akoo in sot nu suwos.’”