< Psalms 95 >
1 Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a kọ orin ayọ̀ sí Olúwa, ẹ jẹ́ kí a kígbe sókè sí àpáta ìgbàlà wa.
Enketa Ra Anumzamofona muse zagame huta agi'a ahentsga nehuta, tagu'ma nevazia Havegi Ra Anumzamofona ranke huta agi'a ahentesga hanune.
2 Ẹ jẹ́ kí a wá sí iwájú rẹ̀ pẹ̀lú ọpẹ́ kí a sì pòkìkí rẹ̀ pẹ̀lú ohun èlò orin àti ìyìn.
Enketa Agri avuga vuta susu hunenteta, muse zagame huta agi'a ahentesga hamneno.
3 Nítorí Olúwa Ọlọ́run títóbi ni, ọba tí ó tóbi ju gbogbo òrìṣà lọ.
Na'ankure Ra Anumzamo'a marerisa Anumza mani'neno, maka havi anumzantamina zamagatereno, ugota Kini mani'ne.
4 Ní ọwọ́ rẹ̀ ni ọ̀gbun ilẹ̀ wà, ṣóńṣó orí òkè tirẹ̀ ní ṣe.
Ama mopafima kerima huno ame fenkame'ma urami'neregati'ma vuno, ame'nagame marerigatere'nea agonaregama vu'neana, ana maka Anumzamofo azampi me'ne.
5 Tirẹ̀ ni Òkun, nítorí òun ni ó dá a àti ọwọ́ rẹ̀ ni ó fi dá ìyàngbẹ ilẹ̀.
Hagerina Anumzamo tro hu'negu huno, Agri suza me'ne. Ana zanke huno ho'mu mopa azanuti tro hu'ne.
6 Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a foríbalẹ̀ kí a sìn ín, ẹ jẹ́ kí a kúnlẹ̀ níwájú Olúwa ẹni tí ó dá wa,
Enketa kepri huta mono hunenteta, Ra Anumo'ma tagri'ma tro'ma hurante'nea ne' avuga tarena reta monora huntesune.
7 nítorí òun ni Ọlọ́run wa, àwa sì ni ènìyàn pápá rẹ̀, àti ọ̀wọ́ ẹran ni abẹ́ ìpamọ́ rẹ̀. Lónìí tí ìwọ bá gbọ́ ohùn rẹ̀,
Na'ankure Agra tagri Anumza mani'neankino, sipisipi afu'tamima kegavama nehiaza huno kegava hurantegeta, Agri azampi mani'none. Ana hu'neanki, meninena tamagesa ante'neta Agri agerura antahiho.
8 “Ẹ má ṣe sé ọkàn yín le gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ṣe ní Meriba, àti bí ẹ ti ṣe ní ọjọ́ náà ní Massa ní aginjù,
Ra Anumzamo huno, Israeli vahe'mo'zama hagege kokampima ne-eza, Meriba kumaku'ma Masa kumarema nehaza kumatema, zamagu'a kafama erigi'naza zana huta tamagu'a kafana eri onkiho.
9 nígbà tí àwọn baba yín dán mi wò tí wọn wádìí mi, tí wọn sì rí iṣẹ́ mi.
Hagi tamagehe'moza hagege kokampima manine'za, maka zama eri fore'ma hua zana ko ke'nazanagi, Nagri hanave kenaku renahe'za ke'naze.
10 Fún ogójì ọdún ni èmi fi bínú sí ìran náà; mo wí pé, ‘Wọ́n jẹ́ ènìyàn tí ọkàn wọn ṣáko lọ wọn kò sì mọ ọ̀nà mi.’
Hagi 40'a kafumofo agu'afina nagote nezmantena amanage hu'na hu'noe, ama vahe'mo'za kana atre'za hazanegre'za, nagrama hihoma hu'na huzmantoa nanekea amagera nontaze.
11 Nítorí náà ni mo kéde ìbúra nínú ìbínú mi, ‘Wọn kì yóò wọ ibi ìsinmi mi.’”
Ana'ma hu'nazagu hu'na tusi narimpa ahenezmante'na, amanage hu'na huvempa hu'noe. Nagrama huama hu'na, tamisugetama ome mani fru hugahazema hu'noa mopafina uofretfa hugahaze (Hibru 4:3).