< Psalms 94 >

1 Olúwa Ọlọ́run ẹni tí ń gbẹ̀san, Ọlọ́run ẹni tí ń gbẹ̀san.
Hina Gode, Di da Gode amo da se imunusa: dawa: Dia ougi hou olelema!
2 Gbé ara rẹ sókè, ìwọ onídàájọ́ ayé; san ẹ̀san fún agbéraga ohun tí ó yẹ wọ́n.
Di da fifi asi gala dunu huluane ilima fofada: su esala! Di wa: legadole amola hina: da: ima hidale nodone hamobe dunu ilima hi giadofale hamobe defele amo dabe ima!
3 Báwo ní yóò ti pẹ́ tó, Olúwa tí àwọn ẹni búburú yóò kọ orin ayọ̀?
Habowali seda wadela: i hou hamosu dunu da nodoma: bela: ? Hina Gode, habowali seda ganoma: bela: ?
4 Wọ́n ń sọ̀rọ̀ ìgbéraga jáde; gbogbo àwọn olùṣe búburú kún fún ìṣògo.
Wadela: le hamoi dunu da habowali seda nodonanoma: bela: , amola ea wadela: le hamoi amoga hidale sia: noma: bela: ?
5 Wọ́n fọ́ àwọn ènìyàn rẹ túútúú, Olúwa: wọ́n pọ́n ilẹ̀ ìní rẹ̀ lójú.
Hina Gode, ilia da Dia dunu amo fane dalega: le sala, amalu ilia da Dimagai dunu ososa: gilisisa.
6 Wọ́n pa àwọn opó àti àlejò, wọ́n sì pa àwọn ọmọ aláìní baba.
Ilia da uda didalo amola guluba: mano amola sofe misi dunu ninia soge ganodini esalebe dunu amo huluane fane lelegesa.
7 Wọ́n sọ pé, “Olúwa kò rí i; Ọlọ́run Jakọbu kò sì kíyèsi i.”
Ilia da amane, sia: sa “Hina Gode Ea da nini hame ba: sa. Isala: ili Gode da nini hame dawa: digi.”
8 Kíyèsi i, ẹ̀yin aláìlóye nínú àwọn ènìyàn; ẹ̀yin aṣiwèrè, nígbà wo ni ẹ̀yin yóò lóye?
Na dunu fi! Dilia da abuli gagaoui agoane ganoma: bela: ? Dilia da habogala noga: le dawa: ma: bela: ?
9 Ẹni tí ó gbin etí, ó lè ṣe aláìgbọ́ bí? Ẹni tí ó dá ojú? Ó ha lè ṣe aláìríran bí?
Dilia da adi dawa: bela: ? Gode da ninia ge hahamoi. E da sia: hame nabala: ? Gode da ninia si hahamoi. E da hame ba: sala: ?
10 Ẹni tí ń bá orílẹ̀-èdè wí, ṣé kò lè tọ́ ni ṣọ́nà bí? Ẹni tí ń kọ́ ènìyàn ha lè ṣàìní ìmọ̀ bí?
E da fifi asi gala ilima ouligisa! E da ilima se bidi ima: bela: ? E da osobo bagade dunu huluane ilima olelesu dunu. E da dawa: hame ganabela: ?
11 Olúwa mọ èrò inú ènìyàn; ó mọ̀ pé asán ni wọ́n.
Hina Gode da dunu huluane ilia asigiga dawa: be huluane dawa: sa, E da ilia dawa: su da hamedene liligi amo dawa:
12 Ìbùkún ni fún ènìyàn náà tí ìwọ bá wí, Olúwa, ẹni tí ìwọ kọ́ nínú òfin rẹ,
Hina Gode! Nowa dunu amo Di da ema Dia sema olelebe. e da hahawane bagade gala!
13 Ìwọ gbà á kúrò nínú ọjọ́ ibi, títí a ó fi wa ihò sílẹ̀ fún ẹni búburú.
Bidi hamosu eno da ema mae doaga: ma: ne, Di da helefisu ema iaha, amogainini wadela: i hou hamosu dunu ili sa: ima: ne uli dogoi da dogosa.
14 Nítorí Olúwa kò ní kọ àwọn ènìyàn rẹ̀ sílẹ̀, Òun kò sì ní kọ ilẹ̀ ìní rẹ̀ sílẹ̀.
Hina Gode da Ea dunu fi hame fisiagamu. E da Ea dunu fi ilima hame gogolemu.
15 Ìdájọ́ yóò padà sí òdodo, àti gbogbo àwọn ọlọ́kàn dídúró ṣinṣin yóò tẹ̀lé e lẹ́yìn.
Moloidafa fofada: su hou da fofada: su diasu ganodini bu ba: mu, amola moloidafa dunu ilia da amo hou fuligala: mu.
16 Ta ni yóò dìde fún mi sí àwọn olùṣe búburú? Tàbí ta ni yóò dìde sí àwọn oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ fún mi?
Nowa da wadela: i hou hamosu amoma higale nama ga: musa: wa: legadobela: ? Nowa da wadela: i hou hamosu dunu ilima higale, namagale aligibala: ?
17 Bí kò ṣe pé Olúwa fún mi ní ìrànlọ́wọ́, èmi fẹ́rẹ̀ máa gbé ní ilẹ̀ tí ó dákẹ́.
Hina Gode da na hame fidi ganiaba, na da hedolowane ouiya: i soge amoga asi gala: loba.
18 Nígbà tí mo sọ pé, “Ẹsẹ̀ mi ń yọ̀”, Olúwa, ìfẹ́ rẹ̀ ni ó tì mí lẹ́yìn.
Na da amane sia: i “Na da dafabe!” be Hina Gode Dia mae fisili asigidafa hou amoga, Dia na fidi.
19 Nígbà tí àníyàn ńlá wà nínú mi, ìtùnú rẹ̀ mú ayọ̀ sí ọkàn mi.
Habogala na da da: i dione dadawa: sea, Di da na lalesalawene hahawane hamosa.
20 Ìjọba ìbàjẹ́ ha lè kẹ́gbẹ́ pẹ̀lú rẹ ẹni tí ń fi òfin dì mọ́ ìwà ìkà?
Di da giadofale fofada: su dunu ilima hahamomu hou da hame gala, amo ilia da giadofale fofada: su hamoma: ne sia: sa, amola amo ilia da noga: i dunu amo fane legemusa: , wamo sia: ilegele amola molole hamosu dunu amo fane lelegesa.
21 Wọ́n kó ara wọn jọ sí olódodo wọ́n sì ń dá àwọn aláìṣẹ̀ lẹ́bi sí ikú.
22 Ṣùgbọ́n, Olúwa ti di odi alágbára mi, àti Ọlọ́run mi ni àpáta nínú ẹni tí mo ti ń gba ààbò.
Be na: Hina Gode da na gaga: sa. E da na ouligisa.
23 Òun yóò san ẹ̀san ibi wọn fún wọn yóò sì pa wọ́n run nítorí búburú wọn Olúwa Ọlọ́run wa yóò pa wọ́n run.
Be eno dunu ilia da wadela: i hou hamobeba: le, Ninia Hina Gode da ilima se bidi imunu, amola ilia da wadela: i hou hamobeba: le ili gugunufinisimu.

< Psalms 94 >