< Psalms 90 >
1 Àdúrà Mose ènìyàn Ọlọ́run. Olúwa, ìwọ ti jẹ́ ibùgbé wa ní gbogbo ìran dé ìran.
Hina Gode, Di da eso huluane ninia esalebe galu.
2 Kí a tó bí àwọn òkè ńlá àti kí ìwọ tó dá ilẹ̀ àti ayé, láti ayérayé dé ayérayé ìwọ ni Ọlọ́run.
Musa: dafa Di da agolo soge amola osobo bagade amo hame hahamoiawane, Di da mae dagole fifi ahoanusu Gode esalu amola Di da ninia Gode esalumu.
3 Ìwọ yí ènìyàn padà sí erùpẹ̀, wí pé, “Padà sí erùpẹ̀, ìwọ ọmọ ènìyàn.”
Di da nini musa: esalua amogai buhagima: ne sia: sa. Di da nini afadenene bu gulu hamosa.
4 Nítorí pé ìgbà tí ẹgbẹ̀rún ọdún bá kọjá lójú rẹ, bí àná ni ó rí, bí ìgbà ìṣọ́ kan lóru.
Ode 1,000 gidigisia, amo Dia ba: sea da ha afaedafa agoai ba: sa, amo da aiya eso baligi amo agoai ba: sa, amola eso dunumunidafa gasia agoai ba: sa.
5 Ìwọ gbá ènìyàn dànù nínú oorun ikú; wọ́n dàbí koríko tuntun ní òwúrọ̀.
Di da nini hano heda: iga mini ahoabe agoane gisa ahoa, be ninia golaia ba: be amoali seda da hame gala. Nini da gisi fage hahabe fadegalalu heda: le osomo amo da falegalu bu daeya biobe agoai gala.
6 Lóòtítọ́, ní òwúrọ̀, ó yọ tuntun ní àṣálẹ́ ni yóò gbẹ, tí yóò sì rẹ̀ dànù.
7 A pa wá run nípa ìbínú rẹ nípa ìbínú rẹ ara kò rọ̀ wá.
Nini da Dia ougi hou amoga gugunufinisi dagoi, nini da Dia gasa bagade ougi hou amoga beda: i gala.
8 Ìwọ ti gbé ẹ̀ṣẹ̀ wa ka iwájú rẹ, àti ohun ìkọ̀kọ̀ wa nínú ìmọ́lẹ̀ iwájú rẹ.
Di da ninia wadela: i hou nini wamo hamobe Dia ba: be amo huluane Dia midadi ligisisa.
9 Gbogbo ọjọ́ wa ń kọjá lọ lábẹ́ ìbínú rẹ; àwa ń lo ọjọ́ wa lọ bí àlá tí à ń rọ́.
Ninia fifi ahoanusu da Dia ougi hou amoga gasiguda: le dunumuniginisisa, amola sia: sadoga sia: sea fofonobona ahoabe agoai gala. 80
10 Àádọ́rin ọdún ni iye ọjọ́ ọdún wá, bi ó sì ṣe pé nípa agbára tí wọn bá tó ọgọ́rin ọdún, agbára nínú làálàá pẹ̀lú ìbànújẹ́ ni, nítorí pé a kò ní pẹ́ gé e kúrò, àwa a sì fò lọ.
Nini da ode 80agoane esalumu galu, be amomane ninia da ode 70 amoga fawane doaga: sa, ninia da gasa galu ganiaba, ilia ninima gaguli mabe da bidi hamosu amola disu fawane gala, esalusu da gadenene baligimu, amola ninia da asi hame ba: mu.
11 Ta ni ó mọ agbára ìbínú rẹ? Gẹ́gẹ́ bí ẹ̀rù rẹ, bẹ́ẹ̀ ni ìbínú rẹ.
Nowa da Dia gasa bagade ougi hou amo bagade nabibala: ? Dia ougi hou gasa bagade mabe amoga beda: su hou da Nowa dawa: ma: bela: ?
12 Kọ́ wa bí a ti ń kaye ọjọ́ wa dáradára, kí àwa ba à lè fi ọkàn wa sípa ọgbọ́n.
Ninia esalusu da habowali seda ganumu, amo ninima olelema! Amasea ninia da noga: le dawa: su dunu esalumu.
13 Yípadà, Olúwa! Yóò ti pẹ́ tó? Ṣàánú fún àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ.
Dia ougi hou da habowali seda dialoma: bela: ? Hina Gode, Dia hawa: hamosu dunuma asigima!
14 Tẹ́ wa lọ́rùn ní òwúrọ̀ nínú ìṣeun ìfẹ́ rẹ, kí àwa kí ó lè kọrin fún ayọ̀ kí inú wa sì dùn ní gbogbo ọjọ́.
Eso huluane hahabe Dia da nini Dia mae fisili asigidafa hou amoga ianoma, amasea ninia da esaleawane Dima nodone gesami hahawane hea: lumu.
15 Mú inú wa dùn bí ọjọ́ tí ìwọ ti pọ́n wa lójú, fún ọjọ́ púpọ̀ tí àwa ti rí wàhálà.
Di da ode bagohame amoga da: i diosu fawane ninima ianusu. Be waha Di da ninima hahawane hou bagade ima.
16 Jẹ́ kí a fi iṣẹ́ rẹ̀ han àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀, ògo rẹ̀ sí àwọn ọmọ wọn.
Ninia da Dia hawa: hamosu dunu. Ninia da Dia hamobe hou bagadedafa amo ba: ma: ma. Niniga fifi ahoanebe ilia da Dia Hina bagade hou ba: ma: ma.
17 Jẹ́ kí ẹwà Olúwa Ọlọ́run wa wà lára wa; fi ìdí iṣẹ́ ọwọ́ wa múlẹ̀ lára wa, bẹ́ẹ̀ ni, kí ó sì fi ìdí iṣẹ́ ọwọ́ wa múlẹ̀.
Ninia Hina Gode, Dia hahawane dogolegele fidisu hou da ninima dialoma: ma. Ninia hamobe huluane da didili hamoma: ma.