< Psalms 9 >

1 Fún adarí orin. Ní ti ohun orin. “Ní ti ikú ọmọ.” Saamu ti Dafidi. Èmi ó yìn ọ́, Olúwa, pẹ̀lú gbogbo ọkàn mi; èmi ó sọ ti ìyanu rẹ gbogbo.
[Laayaeh neh aka mawt ham David kah tingtoenglung] BOEIPA te ka lungbuei boeih neh ka uem vetih, namah kah khobaerhambae te boeih ka doek ni.
2 Inú mi yóò dùn, èmi yóò sì yọ̀ nínú rẹ; èmi ó kọrin ìyìn sí orúkọ rẹ, Ìwọ Ọ̀gá-Ògo jùlọ.
Namah dongah ka kohoe vetih sundaep ni, Na ming Khohni te ka tingtoeng ni.
3 Àwọn ọ̀tá mi pẹ̀yìndà; wọ́n kọsẹ̀ wọn sì ṣègbé níwájú rẹ.
Ka thunkha rhoek loh ha loe uh vaengah a hnuk la paloe uh tih na hmai ah milh uh.
4 Nítorí ìwọ ti di òtítọ́ àti ọ̀ràn mi mú; ìwọ ti jókòó lórí ìtẹ́ rẹ, láti ṣe ìdájọ́ òdodo.
Ka hamsum nan khueh dongah ka dumlai khaw ngolkhoel dongah na ngol thil tih duengnah neh lai nan tloek.
5 Ìwọ ti bá orílẹ̀-èdè wí, Ìwọ sì ti pa ẹni búburú run; Ìwọ ti yọ orúkọ wọn kúrò láé àti láéláé.
Namtom rhoek khaw na tluung tih halang te na milh sak. A ming te kumhal duela na phae yoeyah.
6 Ìparun àìlópin ti borí àwọn ọ̀tá, ìwọ ti fa àwọn ìlú wọn tu; àní ìrántí wọn sì ti ṣègbé.
Thunkha te a yoeyah la imrhong cung uh. Khopuei rhoek khaw na phuk tih amih kah poekkoepnah khaw bing coeng.
7 Olúwa jẹ ọba títí láé; ó ti gbé ìtẹ́ rẹ̀ kalẹ̀ fún ìdájọ́.
Tedae BOEIPA tah kumhal duela ngol ham amah kah laitloeknah ngolkhoel te a rhoekbah coeng.
8 Òun yóò sì ṣe ìdájọ́ ayé ní òdodo; yóò ṣe àkóso ènìyàn pẹ̀lú òdodo.
Te dongah lunglai he duengnah neh lai a tloek vetih, namtu rhoek ham vanatnah neh lai a tloek ni.
9 Olúwa ni ààbò fún àwọn tí a ni lára, ibi ìsádi ní àkókò ìpọ́njú.
Te phoeiah BOEIPA tah hlanghnaep pahnap aka yook ham mueirhih tue vaengkah imsang la om.
10 Àwọn tí ó mọ orúkọ rẹ yóò gbẹ́kẹ̀lé ọ, nítorí, Olúwa, kò kọ àwọn tó ń wá a sílẹ̀.
Nang aka tlap tah BOEIPA loh na hnoo pawt dongah nang ming aka ming tah namah dongah pangtung ni.
11 Kọ orin ìyìn sí Olúwa, tí o ń jẹ ọba ní Sioni; kéde láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, ohun tí ó ṣe.
Zion ah aka ngol BOEIPA te tingtoeng uh lamtah, a bibi te pilnam rhoek taengah puen pa uh.
12 Nítorí ẹni tí ó ń gbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ rántí; òun kò kọ ẹkún àwọn tí a pọ́n lójú.
Amih taengah thii phu aka suk loh, mangdaeng kodo kah pangngawlnah te a poek tih hnilh pawh.
13 Olúwa, wo bí àwọn ọ̀tá ṣe ń ṣe inúnibíni sí mi! Ṣàánú, kí o sì gbé mí sókè kúrò ní ẹnu-ọ̀nà ikú,
Aw BOEIPA kai n'rhen lah. Ka lunguet taengkah phacipphabaem he ham hmu lamtah dueknah vongka lamkah kai he m'pomsang lah.
14 kí èmi kí ó lè sọ ti ìyìn rẹ ni ẹnu-ọ̀nà àwọn ọmọbìnrin Sioni àti láti máa yọ̀ nínú ìgbàlà rẹ.
Te daengah ni Zion nu kah vongka ah nang koehnah boeih a doek uh vetih, namah kah khangnah dongah ka omngaih eh.
15 Àwọn orílẹ̀-èdè ti jì sí kòtò tí wọn ti gbẹ́; ẹsẹ̀ wọn ni àwọ̀n tí wọ́n dẹ sílẹ̀ kọ́.
Namtom rhoek loh amamih kah vaam a saii uh khuila amamih buek uh tih a dongrhui a thing uh dongah a kho man.
16 A mọ Olúwa nípa òdodo rẹ̀; àwọn ènìyàn búburú ni a dẹ́kun mú nípa iṣẹ́ ọwọ́ wọn.
Halang te amah kut kah bisai loh a hlaeh daengah ni, BOEIPA loh a tiktamnah a saii te a ming. Phungding ol (Selah)
17 Àwọn ènìyàn búburú ni a ó dà sí isà òkú, àti gbogbo orílẹ̀-èdè tí ó gbàgbé Ọlọ́run. (Sheol h7585)
Pathen aka hnilh namtom boeih neh halang rhoek te Saelkhui la voei uh ni. (Sheol h7585)
18 Ṣùgbọ́n àwọn aláìní ni a kò ní gbàgbé láéláé, ìrètí àwọn ti ó tálákà ni a kì yóò gbàgbé láéláé.
Tedae khodaeng te yoeyah la hnilh pawt vetih mangdaeng kodo kah ngaiuepnah khaw a yoeyah la pat mahpawh.
19 Dìde, Olúwa, má ṣe jẹ́ kí ènìyàn borí; jẹ́ kí a ṣe ìdájọ́ àwọn orílẹ̀-èdè ni iwájú rẹ.
Aw BOEIPA thoo lah, hlanghing loh n'tanglue thil boel saeh. Namtom he namah hmuh ah laitloek pah lah.
20 Lù wọ́n pẹ̀lú ìpayà, Olúwa; jẹ́ kí àwọn orílẹ̀-èdè mọ̀ pé ènìyàn lásán ni wọ́n. (Sela)
Aw BOEIPA amih te mueipuelnah na khueh daengah ni amih te hlanghing la namtom loh a ming uh eh. (Selah)

< Psalms 9 >