< Psalms 89 >

1 Maskili ti Etani ará Esra. Èmi kọrin títóbi ìfẹ́ Olúwa títí láé; pẹ̀lú ẹnu mi ní èmi yóò jẹ́ kí a mọ òtítọ́ rẹ láti ìran dé ìran.
En undervisning Ethans, dens Esrahitens. Jag vill sjunga om Herrans nåde evinnerliga, och hans sanning förkunna med minom mun, ifrå slägte till slägte;
2 Èmi ó wí pé, ìfẹ́ rẹ dúró títí láé, pé ìwọ gbe òtítọ́ rẹ kalẹ̀ ní ọ̀run fúnra rẹ̀.
Och säger alltså, att en evig nåd skall uppgå; och du varder dina sanning i himmelen troliga hållandes.
3 Ìwọ wí pé, “Èmi ti dá májẹ̀mú pẹ̀lú àwọn àyànfẹ́ mi mo ti búra fún Dafidi ìránṣẹ́ mi.
Jag hafver gjort ett förbund med minom utkorade; minom tjenare David hafver jag svorit:
4 ‘Èmi ó fi ìdí irú-ọmọ rẹ múlẹ̀ títí láé èmí ó sì máa gbe ìtẹ́ rẹ ró láti ìran dé ìran.’”
Jag skall förskaffa dig en evig säd, och bygga din stol ifrå slägte till slägte. (Sela)
5 Àwọn ọ̀run yóò máa yin iṣẹ́ ìyanu rẹ, Olúwa, òtítọ́ rẹ ni ìpéjọpọ̀ àwọn ẹni mímọ́.
Och himlarna, Herre, skola prisa din under, och dina sanning, uti de heligas församling.
6 Ta ni ó wà ní ọ̀run tí a lè fiwé Olúwa? Ta ni nínú àwọn ọmọ alágbára ti a lè fiwé Olúwa?
Ty ho kan i skyn liknas vid Herran; och ibland gudarnas barn Herranom lik vara?
7 Nínú àjọ ìgbìmọ̀ ẹni mímọ́, wọ́n bẹ̀rù Ọlọ́run gidigidi; ó sì ní ìbùyìn fún ju gbogbo àwọn tí ó yí i ká.
Gud är fast mägtig uti de heligas församling, och underlig öfver alla de som omkring honom äro.
8 Olúwa Ọlọ́run alágbára, ta ló dàbí rẹ ìwọ jẹ́ alágbára, Olúwa, òtítọ́ rẹ sì yí ọ ká.
Herre Gud Zebaoth, ho är såsom du, en mägtig Herre? Och din sanning är allt omkring dig.
9 Ìwọ ń darí ríru omi Òkun; nígbà tí ó ru àwọn omi sókè, ìwọ mú wọn parọ́rọ́.
Du råder öfver det stormande hafvet; du styrer dess böljor, när de upphäfva sig.
10 Ìwọ ni ó ti ya Rahabu pẹ́rẹpẹ̀rẹ bí ẹni tí a pa; ìwọ ti fi apá ọwọ́ agbára rẹ tú àwọn ọ̀tá rẹ ká.
Du slår Rahab till döds; du förströr dina fiendar, med dinom starka arm.
11 Tìrẹ ní àwọn ọ̀run, ayé pẹ̀lú jẹ́ tìrẹ: ayé àti ohun gbogbo tí ó wà nínú rẹ̀: ìwọ ti gbé wọn kalẹ̀.
Himmel och jord äro din; du hafver grundat jordenes krets, och hvad deruti är.
12 Gúúsù àti àríwá ìwọ ni ó dá wọn; Tabori àti Hermoni ń fi ayọ̀ yin orúkọ rẹ.
Norr och söder hafver du skapat; Thabor och Hermon fröjdar sig i ditt Namn.
13 Ìwọ ní apá agbára; agbára ní ọwọ́ rẹ, gíga ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ.
Du hafver en väldig arm; stark är din hand, och hög är din högra hand.
14 Òdodo àti òtítọ́ ni ìpìlẹ̀ ìtẹ́ rẹ: ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ àti òtítọ́ ń lọ síwájú rẹ.
Rättfärdighet och dom är dins stols stadfästelse; nåd och sanning äro för ditt ansigte.
15 Ìbùkún ni fún àwọn ènìyàn tí wọn mọ ohùn ayọ̀ nì, Olúwa wọ́n ó máa rìn ní ìmọ́lẹ̀ ojú rẹ.
Väl är de folke, som fröjdas kan; Herre, de skola vandra i dins ansigtes ljus.
16 Wọn ń ṣògo nínú orúkọ rẹ̀ ní gbogbo ọjọ́, wọn ń yin òdodo rẹ.
De skola dagliga öfver ditt Namn glade vara, och i dine rättfärdighet härlige vara.
17 Nítorí ìwọ ni ògo agbára wọn; nípa ojúrere ni ìwo wá ń ṣògo.
Ty du äst deras starkhets berömmelse, och genom dina nåde skall du upphöja vårt horn.
18 Nítorí ti Olúwa ni asà wa, ọba wa sì ni Ẹni Mímọ́ Israẹli.
Ty Herren är vår sköld, och den Helige i Israel är vår Konung.
19 Nígbà náà ni ìwọ sọ̀rọ̀ nínú ìran, sí àwọn olóòtítọ́ rẹ, wí pé, “Èmi ti gbé adé kalẹ̀ sórí ẹni tí ó lágbára, èmi ti gbé ẹni tí a yàn láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn ga.
På den tiden talade du i en syn till dina heliga, och sade: Jag hafver uppväckt en hjelta, den hjelpa skall; jag hafver upphöjt en utkoradan utu folket.
20 Èmi ti rí Dafidi ìránṣẹ́ mi; pẹ̀lú òróró mímọ́ mi ni mo fi yàn án.
Jag hafver funnit min tjenare David; jag hafver smort honom med mina helga oljo.
21 Ìgbà gbogbo ni ọwọ́ mi yóò máa wà pẹ̀lú rẹ̀ apá mí yóò sì fi agbára fún un.
Min hand uppehåller honom, och min arm skall styrka honom.
22 Àwọn ọ̀tá kì yóò borí rẹ̀, àwọn ènìyàn búburú kì yóò rẹ̀ ẹ́ sílẹ̀.
Fienderna skola icke vara honom öfvermägtige, och de orättfärdige skola icke förtrycka honom;
23 Èmi yóò run àwọn ọ̀tá rẹ níwájú rẹ èmi yóò lu àwọn tí ó kórìíra rẹ bolẹ̀.
Utan jag skall slå hans ovänner för honom, och de honom hata, vill jag plåga.
24 Òtítọ́ mi àti ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ yóò wà pẹ̀lú rẹ àti ní orúkọ mi ni a ó gbé ìwo rẹ ga.
Men min sanning och nåd skall när honom vara; och hans horn skall i mitt Namn upphöjdt varda.
25 Èmi ó gbé ọwọ́ rẹ lórí òkun, àti ọwọ́ ọ̀tún rẹ lórí àwọn odo ńlá.
Jag skall sätta hans hand uti hafvet, och hans högra hand uti älfverna.
26 Òun yóò kígbe sí mi pé, ‘Ìwọ ni baba mi, Ọlọ́run mi, àti àpáta ìgbàlà mi!’
Han skall kalla mig alltså: Du äst min fader, min Gud och tröst, den mig hjelper.
27 Èmi yóò ṣe é ni àkọ́bí mi, ẹni gíga ju àwọn ọba ayé.
Och jag skall göra honom till första sonen, den aldrahögsta ibland Konungarna på jordene.
28 Títí láé ni èmi yóò pa ìfẹ́ dídúró ṣinṣin mọ́ fún un, àti májẹ̀mú mi pẹ̀lú rẹ̀ yóò dúró gbọingbọin.
Jag vill behålla honom mina nåd evinnerliga, och mitt förbund skall honom fast blifva.
29 Èmi ó fi ìdí irú-ọmọ rẹ̀ múlẹ̀ títí láé, àti ìtẹ́ rẹ gẹ́gẹ́ bí ọ̀run ti wà láé.
Jag skall gifva honom en evig säd, och hans stol uppehålla, så länge himmelen varar.
30 “Bí àwọn ọmọ rẹ̀ bá kọ òfin mi sílẹ̀ tí wọn kò sì rìn gẹ́gẹ́ bí ìlànà mi.
Men om hans barn min lag öfvergifva, och i minom rättom icke vandra;
31 Tí wọn bá ba ìlànà mi jẹ́ tí wọn kò sì pa àṣẹ mi mọ́,
Om de mina stadgar ohelga, och min bud icke hålla;
32 nígbà náà ni èmi ó fì ọ̀gọ̀ bẹ ìrékọjá wọn wò; àti ẹ̀ṣẹ̀ wọn pẹ̀lú pàṣán;
Så vill jag hemsöka deras synd med ris, och deras missgerningar med plågor.
33 ṣùgbọ́n èmi kò ní mú ìfẹ́ mi tí ó dúró ṣinṣin kúrò lọ́dọ̀ rẹ, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò jẹ́ kí òtítọ́ mi kí ó yẹ̀.
Men mina nåd vill jag icke vända ifrå honom, och icke låta mina sanning fela.
34 Èmi kì yóò sẹ́ májẹ̀mú mi, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò yí ọ̀rọ̀ tí ó ti ẹnu mi jáde padà.
Jag vill icke ohelga mitt förbund, och icke ogildt göra hvad af minom mun utgånget är.
35 Lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo ni èmi ti fi ìwà mímọ́ mi búra; èmi kì yóò purọ́ fún Dafidi.
Jag hafver en gång svorit vid mina helighet: Jag vill icke ljuga for David;
36 Irú-ọmọ rẹ yóò dúró títí láé, àti ìtẹ́ rẹ̀ yóò dúró bí oòrùn níwájú mi.
Hans säd skall evig vara, och hans stol för mig såsom solen.
37 A ó fi múlẹ̀ títí láé bí òṣùpá, àti bi ẹlẹ́rìí òtítọ́ ni ọ̀run.” (Sela)
Såsom månen skall han evinnerliga vid magt hållen varda, och såsom de vittne i skyn viss vara. (Sela)
38 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ìwọ ti ṣá tì, ìwọ sì kórìíra; ìwọ kún fún ìrunú sí ẹni àmì òróró rẹ.
Men nu bortdrifver du och förkastar, och vredgas med dinom smorda.
39 Ìwọ ti sọ májẹ̀mú ìránṣẹ́ rẹ di òfo; ìwọ tàbùkù adé rẹ nínú eruku.
Du bryter dins tjenares förbund, och trampar hans krono neder på jordena.
40 Ìwọ ti wó gbogbo àwọn odi rẹ̀ ìwọ sọ ibi gíga rẹ̀ di ahoro.
Du nederrifver alla hans murar, och låter hans fäste afbrytas.
41 Àwọn tí ń kọjá lọ fi ṣe ìjẹ; ó ti di ẹ̀gàn àwọn olùbágbé rẹ̀.
Honom beröfva alle de der framom gå; han är sinom grannom ett gabberi vorden.
42 Ìwọ ti gbé ọwọ́ ọ̀tún ọ̀tá rẹ̀ sókè; ìwọ mú gbogbo ọ̀tá rẹ̀ yọ̀.
Du upphöjer hans ovänners högra hand, och gläder alla hans fiendar.
43 Pẹ̀lú, ìwọ ti yí ojú idà rẹ̀ padà, ìwọ kò sì dúró tì í nínú ogun.
Ock hafver du hans svärds kraft borttagit, och låter honom ingen seger vinna i stridene.
44 Ìwọ ti mú ògo rẹ̀ kùnà, ìwọ si wó ìtẹ́ rẹ̀ palẹ̀ sílẹ̀ẹ́lẹ̀.
Du förstörer hans renhet, och kastar hans stol till jordena.
45 Ìwọ ti gé ọjọ́ èwe rẹ̀ kúrú; ìwọ sì fi ìtìjú bò ó.
Du förkortar hans ungdoms tid, och betäcker honom med blygd. (Sela)
46 Yóò ti pẹ́ tó, Olúwa? Tí ìwọ ó ha fi ara rẹ pamọ́ títí láé? Yóò ti pẹ́ to tí ìbínú rẹ yóò máa jó bí iná?
Herre, huru länge vill du dig så allstinges fördölja; och låta dina grymhet brinna såsom en eld?
47 Rántí bí ọjọ́ mi ti kúrú tó nítorí asán ha ni ìwọ fi ṣẹ̀dá àwọn ènìyàn!
Tänk huru stackot mitt lif är; hvi vill du alla menniskor fåfängt skapat hafva?
48 Ta ni yóò wà láààyè tí kò ní rí ikú rẹ̀? Ta ló lè sá kúrò nínú agbára isà òkú? (Sheol h7585)
Hvilken är den der lefver, och intet ser döden; den sina själ friar utu helvetes hand? (Sela) (Sheol h7585)
49 Olúwa, níbo ni ìṣeun ìfẹ́ rẹ àtijọ́ wà, tí ìwọ ti fi òtítọ́ rẹ búra fún Dafidi?
Herre, hvar är den förra din nåd, den du David i dine sanning svorit hafver?
50 Rántí, Olúwa, bí a ti ń gan àwọn ìránṣẹ́ rẹ; bí èmi ti gbà ní àyà mi láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn,
Tänk, Herre, på dina tjenares försmädelse, den jag bär i mitt sköt, af allom så mångom folkom;
51 ẹ̀gàn tí àwọn ọ̀tá rẹ gàn, Olúwa, tí wọn gan ipasẹ̀ ẹni àmì òróró rẹ.
Dermed, Herre, dine fiender dig försmäda; der de med försmäda, och med fötterna trampa på din smorda.
52 Olùbùkún ní Olúwa títí láé.
Lofvad vare Herren evinnerliga. Amen, Amen.

< Psalms 89 >