< Psalms 88 >

1 Orin. Saamu ti àwọn ọmọ Kora. Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti mahalati leannoti. Maskili ti Hemani ará Esra. Olúwa, Ọlọ́run tí ó gbà mí là, ní ọ̀sán àti ní òru, mo kígbe sókè sí Ọ.
pouczający, od Hemana Ezrachity. PANIE, Boże mego zbawienia, we dnie i w nocy wołam do ciebie.
2 Jẹ́ kí àdúrà mi kí ó wá sí iwájú rẹ; dẹ etí rẹ sí igbe mi.
Niech dojdzie do ciebie moja modlitwa, nakłoń swego ucha na moje wołanie.
3 Nítorí ọkàn mi kún fún ìpọ́njú ọkàn mi sì súnmọ́ isà òkú. (Sheol h7585)
Moja dusza bowiem jest nasycona utrapieniem, a moje życie zbliża się do grobu. (Sheol h7585)
4 A kà mí mọ́ àwọn tí wọ́n lọ sí ọ̀gbun ilẹ̀ èmi dàbí ọkùnrin tí kò ni agbára.
Zaliczono mnie do tych, którzy zstępują do dołu; stałem się jak człowiek bez siły.
5 A yà mí sọ́tọ̀ pẹ̀lú àwọn òkú bí ẹni tí a pa tí ó dùbúlẹ̀ ní ipò ikú, ẹni tí ìwọ kò rántí mọ́, ẹni tí a gé kúrò lára àwọn tí ìwọ ń tọ́jú.
Zaliczono mnie do umarłych; [jestem] jak zabici, którzy leżą w grobie, o których już nie pamiętasz i którzy są odłączeni od twojej ręki.
6 Ìwọ tí ó fi mí sí kòtò jíjìn, ní ibi ọ̀gbun tó ṣókùnkùn.
Strąciłeś mnie w najgłębszy dół, w ciemności, w głębie.
7 Ìbínú rẹ ṣubú lé mi gidigidi; ìwọ ti fi àwọn ìjì rẹ borí mi.
Twój gniew ciąży na mnie i przytłoczyłeś mnie wszystkimi twymi falami. (Sela)
8 Ìwọ tí gba ọ̀rẹ́ mi tí ó súnmọ́ mi kúrò lọ́wọ́ mi ìwọ sì sọ mi di ìríra sí wọn. A há mi mọ́, èmi kò sì le è jáde;
Oddaliłeś ode mnie moich znajomych, uczyniłeś mnie dla nich ohydą; jestem uwięziony i nie mam wyjścia.
9 ojú mi káàánú nítorí ìpọ́njú. Mo kígbe pè ọ́, Olúwa, ní gbogbo ọjọ́; mo na ọwọ́ mi jáde sí ọ.
Moje oko płacze nad moim utrapieniem; wzywam cię, PANIE, codziennie, wyciągam do ciebie swe ręce.
10 Ìwọ ó fi iṣẹ́ ìyanu rẹ hàn fún òkú bi? Àwọn òkú yóò ha dìde láti yìn ọ́ bí?
Czy dla umarłych będziesz czynił cuda? Czy umarli powstaną, aby cię wysławiać? (Sela)
11 A ó ha fi ìṣeun ìfẹ́ rẹ hàn ní ibojì bí, tàbí òtítọ́ rẹ ní ipò ìparun?
Czy w grobie będzie się opowiadać o twoim miłosierdziu, a o twojej wierności – w zniszczeniu?
12 A ha lè mọ iṣẹ́ ìyanu rẹ ní òkùnkùn bí àti òdodo rẹ ní ilẹ̀ ìgbàgbé?
Czy twoje cuda pozna się w ciemnościach, a twoją sprawiedliwość w ziemi zapomnienia?
13 Ṣùgbọ́n mo kígbe sí ọ fún ìrànlọ́wọ́, Olúwa; ní òwúrọ̀ ni àdúrà mí wá sọ́dọ̀ rẹ.
Lecz ja, PANIE, do ciebie wołam; rankiem wita cię moja modlitwa.
14 Olúwa, èéṣe tí ìwọ fi kọ̀ mí tí ìwọ fi ojú rẹ pamọ́ fún mi?
Dlaczego, PANIE, odrzucasz moją duszę i ukrywasz przede mną swoje oblicze?
15 Láti ìgbà èwe mi, ìṣẹ́ ń ṣẹ́ mi, èmi múra àti kú; nígbà tí ẹ̀rù rẹ bá ń bà mí, èmi di gbére-gbère.
Jestem strapiony i od młodości bliski śmierci; znoszę twoją grozę i trwożę się.
16 Ìbínú rẹ ti kọjá lára mi; ìbẹ̀rù rẹ ti gé mi kúrò.
Twój srogi gniew spadł na mnie [i] wyniszczyła mnie twoja groza.
17 Ní gbogbo ọjọ́ ni wọn yí mi ká bí ìkún omi; wọ́n mù mí pátápátá.
Ogarniają mnie co dzień jak woda, wszystkie mnie otaczają.
18 Ìwọ ti mú ọ̀rẹ́ àti olùfẹ́ mi kúrò lọ́dọ̀ mi; òkùnkùn sì jẹ́ ọ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ mi.
Oddaliłeś ode mnie przyjaciela i towarzysza, a moich znajomych – w ciemności.

< Psalms 88 >