< Psalms 88 >

1 Orin. Saamu ti àwọn ọmọ Kora. Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti mahalati leannoti. Maskili ti Hemani ará Esra. Olúwa, Ọlọ́run tí ó gbà mí là, ní ọ̀sán àti ní òru, mo kígbe sókè sí Ọ.
Ezrakhi hoel Heman kah hlohlai aka doo Mahalath aka mawt ham Korah koca rhoek kah Tingtoeng laa Kai kah khangnah Pathen BOEIPA, namah hmaiah khoyin khothaih ka pang.
2 Jẹ́ kí àdúrà mi kí ó wá sí iwájú rẹ; dẹ etí rẹ sí igbe mi.
Ka thangthuinah loh namah mikhmuh la ha pawk saeh. Ka tamlung he na hna kaeng thil lah.
3 Nítorí ọkàn mi kún fún ìpọ́njú ọkàn mi sì súnmọ́ isà òkú. (Sheol h7585)
Ka hinglu he yoethae loh hah coeng tih ka hingnah he Saelkhui a paan coeng. (Sheol h7585)
4 A kà mí mọ́ àwọn tí wọ́n lọ sí ọ̀gbun ilẹ̀ èmi dàbí ọkùnrin tí kò ni agbára.
Tangrhom la aka suntla rhoek neh n'moeh tih a dawn aka sai mueh hlang bangla ka om.
5 A yà mí sọ́tọ̀ pẹ̀lú àwọn òkú bí ẹni tí a pa tí ó dùbúlẹ̀ ní ipò ikú, ẹni tí ìwọ kò rántí mọ́, ẹni tí a gé kúrò lára àwọn tí ìwọ ń tọ́jú.
Aka duek rhoek taengah a rhoe tih phuel kah aka yalh rhok te na ngaidam voel kolla na kut dong lamkah na tuiphih banghui lamni ka om coeng.
6 Ìwọ tí ó fi mí sí kòtò jíjìn, ní ibi ọ̀gbun tó ṣókùnkùn.
Kai he a laedil kah tangrhom ah, khohmuep ah, a cok ah nan khueh.
7 Ìbínú rẹ ṣubú lé mi gidigidi; ìwọ ti fi àwọn ìjì rẹ borí mi.
Na kosi te kai soah na tloeng tih na tuiphu tom neh nan phaep.
8 Ìwọ tí gba ọ̀rẹ́ mi tí ó súnmọ́ mi kúrò lọ́wọ́ mi ìwọ sì sọ mi di ìríra sí wọn. A há mi mọ́, èmi kò sì le è jáde;
Kamah kah hmaiben nawn khaw kai taeng lamkah nan lakhla sak. Amih kah tueilaehkoi la kai nan khueh dongah n'nan uh tih ka coe thai pawh. (Selah)
9 ojú mi káàánú nítorí ìpọ́njú. Mo kígbe pè ọ́, Olúwa, ní gbogbo ọjọ́; mo na ọwọ́ mi jáde sí ọ.
Phacipphabaem khui lamkah nang kang khue ham khaw ka mik kha coeng. BOEIPA namah taengah hnin takuem ka kut ka phuel.
10 Ìwọ ó fi iṣẹ́ ìyanu rẹ hàn fún òkú bi? Àwọn òkú yóò ha dìde láti yìn ọ́ bí?
Aka duek rhoek ham khobaerhambae na saii pah atah sairhai a aka thoo vetih namah n'uem eh? (Selah)
11 A ó ha fi ìṣeun ìfẹ́ rẹ hàn ní ibojì bí, tàbí òtítọ́ rẹ ní ipò ìparun?
Nang kah sitlohnah te phuel khuiah, na uepomnah te Abaddon ah a thui aya?
12 A ha lè mọ iṣẹ́ ìyanu rẹ ní òkùnkùn bí àti òdodo rẹ ní ilẹ̀ ìgbàgbé?
Nang kah khobaerhambae te khohmuep khuiah, namah kah duengnah te lunghnilh kho ah a ming uh aya?
13 Ṣùgbọ́n mo kígbe sí ọ fún ìrànlọ́wọ́, Olúwa; ní òwúrọ̀ ni àdúrà mí wá sọ́dọ̀ rẹ.
Tedae kai loh BOEIPA nang taengah ka pang tih mincang kah ka thangthuinah loh namah n'doe.
14 Olúwa, èéṣe tí ìwọ fi kọ̀ mí tí ìwọ fi ojú rẹ pamọ́ fún mi?
BOEIPA aw ba dongah nim ka hinglu he na hlahpham tih kai taeng lamkah na maelhmai na thuh mai?
15 Láti ìgbà èwe mi, ìṣẹ́ ń ṣẹ́ mi, èmi múra àti kú; nígbà tí ẹ̀rù rẹ bá ń bà mí, èmi di gbére-gbère.
Kai mangdaeng he ka camoe lamkah ka pal coeng. Nang taengkah mueirhih ka phueih tih ka ngaidaeng.
16 Ìbínú rẹ ti kọjá lára mi; ìbẹ̀rù rẹ ti gé mi kúrò.
Na thinsa loh kai soah n'khuk tih namah kah hihhamnah loh kai m'biit uh coeng.
17 Ní gbogbo ọjọ́ ni wọn yí mi ká bí ìkún omi; wọ́n mù mí pátápátá.
Tui bangla kai n'hil uh tih, khohnin yung ah kai malh m'vael.
18 Ìwọ ti mú ọ̀rẹ́ àti olùfẹ́ mi kúrò lọ́dọ̀ mi; òkùnkùn sì jẹ́ ọ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ mi.
Ka lungnah ka paya khaw kai taeng lamkah nan lakhla sak tih khohmuep ni ka hmaiben coeng.

< Psalms 88 >