< Psalms 88 >

1 Orin. Saamu ti àwọn ọmọ Kora. Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti mahalati leannoti. Maskili ti Hemani ará Esra. Olúwa, Ọlọ́run tí ó gbà mí là, ní ọ̀sán àti ní òru, mo kígbe sókè sí Ọ.
Hina Gode na Gaga: sudafa! Na da eso huluane Dima wele sia: nana, amola gasia na da Dia midadi Dima maha.
2 Jẹ́ kí àdúrà mi kí ó wá sí iwájú rẹ; dẹ etí rẹ sí igbe mi.
Na Dima sia: ne gadobe amo nabima! Na da Dia fidima: ne digini wele sia: be amo nabima!
3 Nítorí ọkàn mi kún fún ìpọ́njú ọkàn mi sì súnmọ́ isà òkú. (Sheol h7585)
Bidi hamosu bagohame da nama misiba: le, na da bogomu gadenei. (Sheol h7585)
4 A kà mí mọ́ àwọn tí wọ́n lọ sí ọ̀gbun ilẹ̀ èmi dàbí ọkùnrin tí kò ni agbára.
Na gasa huluane da fisi dagoi! Na da dunu oda agoane bogomu gadenei agoai galebe.
5 A yà mí sọ́tọ̀ pẹ̀lú àwọn òkú bí ẹni tí a pa tí ó dùbúlẹ̀ ní ipò ikú, ẹni tí ìwọ kò rántí mọ́, ẹni tí a gé kúrò lára àwọn tí ìwọ ń tọ́jú.
Na da bogogia: su sogebi amoga dialoma: ne fisi dagoi ba: sa! Na da fane legesu dunu agoane ilia uli dogoi ganodini dialebe agoai amo da Dia fidimu hamedene gogolesa gogoleidafa.
6 Ìwọ tí ó fi mí sí kòtò jíjìn, ní ibi ọ̀gbun tó ṣókùnkùn.
Di da bogoi salasu uli dogoi gududafa amoga na sanasi dagoi. Amo gelabo da gasi dunasi amola sedadedafa.
7 Ìbínú rẹ ṣubú lé mi gidigidi; ìwọ ti fi àwọn ìjì rẹ borí mi.
Dia ougi da na da: i hodo da: iya dioi bagade diala amola amoga na da banenesi diala.
8 Ìwọ tí gba ọ̀rẹ́ mi tí ó súnmọ́ mi kúrò lọ́wọ́ mi ìwọ sì sọ mi di ìríra sí wọn. A há mi mọ́, èmi kò sì le è jáde;
Di da hamobeba: le, na dogolegei dunu da nama gahegisa, amola na dogolegei dunu ilia siga na da wadela: idafa ba: sa. Na da halegale hobeamu hamedei ba: sa.
9 ojú mi káàánú nítorí ìpọ́njú. Mo kígbe pè ọ́, Olúwa, ní gbogbo ọjọ́; mo na ọwọ́ mi jáde sí ọ.
Na da se nababeba: le, ba: mu gogolei. Hina Gode, na da eso huluane Dima wele sia: sa, amola na lobo gaguia gadole sia: ne gadolala.
10 Ìwọ ó fi iṣẹ́ ìyanu rẹ hàn fún òkú bi? Àwọn òkú yóò ha dìde láti yìn ọ́ bí?
Di da bogoi dunuma musa: hame ba: su hou hahamoma: bela? Ilia da bu wa: legadole Dima nodone sia: ma: bela: ?
11 A ó ha fi ìṣeun ìfẹ́ rẹ hàn ní ibojì bí, tàbí òtítọ́ rẹ ní ipò ìparun?
Dunu ilia da Dia mae fisili asigi hou bogoi uli dogoi gelaba ganodini sia: ma: bela: ? Dia didili hamosu da gugununfinisisu soge amo ganodini dialoma: bela: ?
12 A ha lè mọ iṣẹ́ ìyanu rẹ ní òkùnkùn bí àti òdodo rẹ ní ilẹ̀ ìgbàgbé?
Dia hame ba: su liligi hou da, amo gasi sogebi amo ganodini ba: ma: bela: ? Dunu ilia eno dunu amo da bogoi sogega daha hedolo gogolesa. Amo soge ganodini, Dia noga: idafa hou da dialoma: bela: ?
13 Ṣùgbọ́n mo kígbe sí ọ fún ìrànlọ́wọ́, Olúwa; ní òwúrọ̀ ni àdúrà mí wá sọ́dọ̀ rẹ.
Hina Gode, na da Dia na fidima: ne Dima wele sia: sa. Eso huluane hahabe na da Dima sia: ne gadosa.
14 Olúwa, èéṣe tí ìwọ fi kọ̀ mí tí ìwọ fi ojú rẹ pamọ́ fún mi?
Hina Gode, abuliba: le Di da nama higale ba: sala: ? Abuliba: le Di da nama baligi fa: sala?
15 Láti ìgbà èwe mi, ìṣẹ́ ń ṣẹ́ mi, èmi múra àti kú; nígbà tí ẹ̀rù rẹ bá ń bà mí, èmi di gbére-gbère.
Na da goifonoboga ganiniwane se nabasu amola na da bogomu gadenenewane esalusu. Na da Dia dawa: ma: ne se bidi iasu dioi bagadeba: le, amoga sesele gasa hame galebe.
16 Ìbínú rẹ ti kọjá lára mi; ìbẹ̀rù rẹ ti gé mi kúrò.
Dia ougi hou bagadedafa amoga na da banenesi dagoi. Dia gasa fili doagala: su amoga na da gugunufinisi dogoi.
17 Ní gbogbo ọjọ́ ni wọn yí mi ká bí ìkún omi; wọ́n mù mí pátápátá.
Eso huluane ilia da na sisiga: le aliligibi amo ba: sea, da hano hihi heda: i agoai ba: sa, ilia da na beba: le huluane eale disisa.
18 Ìwọ ti mú ọ̀rẹ́ àti olùfẹ́ mi kúrò lọ́dọ̀ mi; òkùnkùn sì jẹ́ ọ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ mi.
Di da na dogolegeidafa ani sasamogene nabe dunu amo na fisiagama: ne hamoi, amola gasi fawane da na sama agoai gala.

< Psalms 88 >