< Psalms 87 >

1 Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Orin. Ó ti fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ sórí òkè mímọ́;
Nkunga bana ba Kole. Wutula fondasio andi ku mongo wunlongo.
2 Olúwa fẹ́ràn ẹnu-ọ̀nà Sioni ju gbogbo ibùgbé Jakọbu lọ.
Yave weti zola mielo mi Sioni viokila bibuangu bioso bimvuandanga Yakobi.
3 Ohun ológo ni a sọ nípa rẹ̀, ìlú Ọlọ́run,
Mambu ma nkembo matubu mu diambu diaku; a divula di Nzambi.
4 “Èmi ó dárúkọ Rahabu àti Babeli láàrín àwọn tí ó jẹ́wọ́ mi: Filistia pẹ̀lú, àti Tire, pẹ̀lú Kuṣi, yóò sọ pé, ‘Èyí ni a bí ní Sioni.’”
“Ndiela yolukila Lahabi ayi Babiloni muidi bobo banzebi; tsi yi Filisiti ayi Tila va kimosi ayi Kutsi: ayi tuba: mutu wawu ku Sioni kabutukila”.
5 Nítòótọ́, ti Sioni ni a ó sọ, “Eléyìí àti eléyìí ni a bí nínú rẹ̀, àti Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo ni yóò fìdí rẹ̀ múlẹ̀.”
Buna mu diambu di Sioni; bela tuba: “Mutu wawu ayi mutu wuna, mu niandi babutukila” ayi Nzambi yizangama, niandi wela kumbieka.
6 Olúwa yóò kọ nínú àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀: “Eléyìí ni a bí ní Sioni.”
Yave wela sonika batu mu buku: “mutu wawu ku Sioni kabutukila.”
7 Àti àwọn olórin àti àwọn tí ń lu ohun èlò orin yóò wí pé, “Gbogbo orísun mi ń bẹ nínú rẹ.”
Bu balembo budi miziki, bela yimbila: “zitho ziama zioso zidi mu ngeyo.”

< Psalms 87 >