< Psalms 87 >

1 Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Orin. Ó ti fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ sórí òkè mímọ́;
Un psalm sau o cântare pentru fiii lui Core. Temelia lui este în munții sfinți.
2 Olúwa fẹ́ràn ẹnu-ọ̀nà Sioni ju gbogbo ibùgbé Jakọbu lọ.
DOMNUL iubește porțile Sionului mai mult decât toate locuințele lui Iacob.
3 Ohun ológo ni a sọ nípa rẹ̀, ìlú Ọlọ́run,
Lucruri glorioase sunt vorbite despre tine, cetatea lui Dumnezeu. (Selah)
4 “Èmi ó dárúkọ Rahabu àti Babeli láàrín àwọn tí ó jẹ́wọ́ mi: Filistia pẹ̀lú, àti Tire, pẹ̀lú Kuṣi, yóò sọ pé, ‘Èyí ni a bí ní Sioni.’”
Voi aminti despre Rahab și Babilon celor ce mă cunosc, iată, Filistia și Tirul, cu Etiopia; acesta s-a născut acolo.
5 Nítòótọ́, ti Sioni ni a ó sọ, “Eléyìí àti eléyìí ni a bí nínú rẹ̀, àti Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo ni yóò fìdí rẹ̀ múlẹ̀.”
Și despre Sion se va spune: Acesta și acela s-a născut în ea, și însuși cel preaînalt o va întemeia.
6 Olúwa yóò kọ nínú àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀: “Eléyìí ni a bí ní Sioni.”
DOMNUL va număra, când va înscrie poporul, că acesta s-a născut acolo. (Selah)
7 Àti àwọn olórin àti àwọn tí ń lu ohun èlò orin yóò wí pé, “Gbogbo orísun mi ń bẹ nínú rẹ.”
Tot așa cântăreții și instrumentiștii vor fi acolo, toate izvoarele mele sunt în tine.

< Psalms 87 >