< Psalms 87 >

1 Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Orin. Ó ti fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ sórí òkè mímọ́;
Nabangon ti siudad ti Apo iti rabaw dagiti nasantoan a banbantay.
2 Olúwa fẹ́ràn ẹnu-ọ̀nà Sioni ju gbogbo ibùgbé Jakọbu lọ.
Ad-adda nga ay-ayaten ni Yahweh dagiti ruangan ti Sion ngem dagiti amin a tolda ni Jacob.
3 Ohun ológo ni a sọ nípa rẹ̀, ìlú Ọlọ́run,
Nadayag a banbanag dagiti naibaga a maipapan kenka, a siudad ti Dios. (Selah)
4 “Èmi ó dárúkọ Rahabu àti Babeli láàrín àwọn tí ó jẹ́wọ́ mi: Filistia pẹ̀lú, àti Tire, pẹ̀lú Kuṣi, yóò sọ pé, ‘Èyí ni a bí ní Sioni.’”
Dakamatek ti Rahab ken Babilonia kadagiti pasurotko. Kitaenyo, adda ti Filistia, ken Tiro, a kaduada ti Etiopia. Naipasngay daytoy sadiay.
5 Nítòótọ́, ti Sioni ni a ó sọ, “Eléyìí àti eléyìí ni a bí nínú rẹ̀, àti Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo ni yóò fìdí rẹ̀ múlẹ̀.”
Maibaganto iti Sion, “Naipasngay ti tunggal maysa kadagitoy kenkuana; ken ti mismo a Kangangatoan ti mangipasdek kenkuana.”
6 Olúwa yóò kọ nínú àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀: “Eléyìí ni a bí ní Sioni.”
Isurat ni Yahweh kabayatan ti panaglislistana kadagiti tattao, “Naipasngay daytoy sadiay.” (Selah)
7 Àti àwọn olórin àti àwọn tí ń lu ohun èlò orin yóò wí pé, “Gbogbo orísun mi ń bẹ nínú rẹ.”
Isu nga ibaga met dagiti kumakanta ken sumasala nga, “Adda kenka dagiti amin nga ubbogko.”

< Psalms 87 >