< Psalms 87 >
1 Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Orin. Ó ti fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ sórí òkè mímọ́;
Thaburi ya Ariũ a Kora Nĩahaandĩte mũthingi wa itũũra rĩake igũrũ rĩa kĩrĩma kĩrĩa kĩamũre;
2 Olúwa fẹ́ràn ẹnu-ọ̀nà Sioni ju gbogbo ibùgbé Jakọbu lọ.
Jehova nĩendete ihingo cia Zayuni gũkĩra ciikaro iria ingĩ ciothe cia Jakubu.
3 Ohun ológo ni a sọ nípa rẹ̀, ìlú Ọlọ́run,
Maũndũ mega nĩmaragio igũrũ rĩaku, wee itũũra inene rĩa Ngai:
4 “Èmi ó dárúkọ Rahabu àti Babeli láàrín àwọn tí ó jẹ́wọ́ mi: Filistia pẹ̀lú, àti Tire, pẹ̀lú Kuṣi, yóò sọ pé, ‘Èyí ni a bí ní Sioni.’”
“Nĩngwandĩka ũhoro wa Rahabu na wa Babuloni thĩinĩ wa arĩa manjũũĩ, Filistia o nakuo, na Turo, hamwe na Kushi, njuge atĩrĩ, ‘Ũyũ aaciarĩirwo Zayuni.’”
5 Nítòótọ́, ti Sioni ni a ó sọ, “Eléyìí àti eléyìí ni a bí nínú rẹ̀, àti Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo ni yóò fìdí rẹ̀ múlẹ̀.”
Ti-itherũ, ũhoro wa Zayuni ũkĩario nĩgũkagwetagwo atĩrĩ, “Ũyũ o na ũũrĩa maaciarĩirwo kuo, na Ũrĩa-ũrĩ-Igũrũ-Mũno we mwene nĩagatũma gũtũũre kũrĩ kũrũmu.”
6 Olúwa yóò kọ nínú àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀: “Eléyìí ni a bí ní Sioni.”
Jehova nĩakandĩka ibuku-inĩ rĩa kĩrĩndĩ ũũ: “Ũyũ aaciarĩirwo Zayuni.”
7 Àti àwọn olórin àti àwọn tí ń lu ohun èlò orin yóò wí pé, “Gbogbo orísun mi ń bẹ nínú rẹ.”
Nao magĩtunga nyĩmbo makaina atĩrĩ, “Ithima ciakwa ciothe irĩ thĩinĩ waku.”