< Psalms 87 >

1 Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Orin. Ó ti fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ sórí òkè mímọ́;
`The salm of the song of the sones of Chore. The foundementis therof ben in hooli hillis;
2 Olúwa fẹ́ràn ẹnu-ọ̀nà Sioni ju gbogbo ibùgbé Jakọbu lọ.
the Lord loueth the yatis of Sion, more than alle the tabernaclis of Jacob.
3 Ohun ológo ni a sọ nípa rẹ̀, ìlú Ọlọ́run,
Thou citee of God, with outen ende; gloriouse thingis ben seide of thee.
4 “Èmi ó dárúkọ Rahabu àti Babeli láàrín àwọn tí ó jẹ́wọ́ mi: Filistia pẹ̀lú, àti Tire, pẹ̀lú Kuṣi, yóò sọ pé, ‘Èyí ni a bí ní Sioni.’”
I schal be myndeful of Raab, and Babiloyne; knowynge me. Lo! aliens, and Tyre, and the puple of Ethiopiens; thei weren there.
5 Nítòótọ́, ti Sioni ni a ó sọ, “Eléyìí àti eléyìí ni a bí nínú rẹ̀, àti Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo ni yóò fìdí rẹ̀ múlẹ̀.”
Whether a man schal seie to Sion, And a man is born ther ynne; and that man altherhiyeste foundide it?
6 Olúwa yóò kọ nínú àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀: “Eléyìí ni a bí ní Sioni.”
The Lord schal telle in the scripturis of puplis; and of these princis, that weren ther ynne.
7 Àti àwọn olórin àti àwọn tí ń lu ohun èlò orin yóò wí pé, “Gbogbo orísun mi ń bẹ nínú rẹ.”
As the dwellyng `of alle that ben glad; is in thee.

< Psalms 87 >